Publicidade

1 Timóteo 1

1 Paulu, aposteli Kristi Jesu gẹ́gẹ́ àṣẹ Ọlọ́run Olùgbàlà wa, àti Jesu Kristi ìrètí wa,

2 Timotiu ọmọ mi nínú ìgbàgbọ́:

Oore-ọ̀fẹ́, àánú àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa wa.

Ìkìlọ̀ lòdì olùkọ́ni èké ti òfin

3 mo ṣe rọ̀ yìn nígbà ń lọ Makedonia, dúró Efesu, àwọn ènìyàn kan lẹ́kun láti ṣe kọ́ ni ̀kọ́ èké mọ́ 4 wọ́n ṣe fiyèsí àwọn ìtàn asán, àti ìtàn ìran aláìlópin. Irú èyí máa ń iyàn jíjà dípò iṣẹ́ ìríjú Ọlọ́run èyí í ṣe ti ìgbàgbọ́. 5 Ète àṣẹ náà ni ìfẹ́ ti ń jáde láti inú ọkàn mímọ́ àti ̀ọkàn rere àti ìgbàgbọ́ àìṣẹ̀tàn. 6 Àwọn ẹlòmíràn ti yapa kúrò wọ́n sápá kan ̀rọ̀ asán. 7 Wọ́n ń fẹ́ ṣe olùkọ́ òfin; òye ohun wọ́n ń wọn tàbí ti ohun wọ́n ń fi ìgboyà tẹnumọ́.

8 Ṣùgbọ́n àwa mọ̀ òfin dára, ènìyàn ó dáradára. 9 a ti mọ̀ , a ṣe òfin fún olódodo, ṣe fún àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, fún àwọn aláìmọ́ àti àwọn ẹlẹ́gàn, fún àwọn ń pa baba àti àwọn ń pa ìyá wọn àti àwọn apànìyàn, 10 fún àwọn àgbèrè, fún àwọn aláyídà, fún àwọn onísòwò-ẹrú, fún àwọn èké, fún àwọn abúra èké, àti ohun mìíràn ó lòdì ̀kọ́ ó kooro. 11 Gẹ́gẹ́ ìyìnrere ti ògo Ọlọ́run olùbùkún, a fi ìtọ́mi.

Oore-ọ̀fẹ́ Olúwa Paulu

12 Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ ẹni ó fún mi agbára, àní Kristi Jesu Olúwa wa, nítorí ó olóòtítọ́ yíyànmí iṣẹ́ rẹ̀. 13 mo tilẹ̀ jẹ́ asọ̀rọ̀-òdì Ọlọ́run , àti onínúnibíni àti ìkà ènìyàn, ṣùgbọ́n mo àánú gbà, nítorí mo ṣe é nínú àìmọ̀ àti àìgbàgbọ́. 14 Oore-ọ̀fẹ́ Olúwa wa pọ̀ rékọjá pẹ̀ìgbàgbọ́ àti ìfẹ́, ń bẹ nínú Kristi Jesu.

15 Òtítọ́ ni ̀rọ̀ náà, ó yẹ fún ìtẹ́wọ́gbà, Jesu Kristi ayé láti gba ẹlẹ́ṣẹ̀ ; nínú àwọn ẹni èmi jẹ́ búburú jùlọ. 16 Ṣùgbọ́n nítorí èyí ni mo ṣe àánú gbà, lára mi, olórí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni Jesu Kristi fi gbogbo ìpamọ́ra rẹ̀ hàn àpẹẹrẹ fún àwọn yóò gbà á gbọ́ ìyè àìnípẹ̀kun ìkẹyìn. 17 Ǹjẹ́ fún ọba ayérayé, àìdíbàjẹ́, àìrí, Ọlọ́run kan ṣoṣo, ni ọlá àti ògo fún láéláé. Àmín.

18 Àṣẹ yìí ni mo pa fún , Timotiu ọmọ mi, gẹ́gẹ́ ìsọtẹ́lẹ̀ wọ̀nyí ó ti ṣáájú nípa rẹ̀, nípasẹ̀ wọ́n ìwọ máa ja ìjà rere; 19 máa ìgbàgbọ́ àti ̀ọkàn rere. Èyí ti àwọn mìíràn ti kúrò lọ́dọ̀ wọn wọ́n ọkàn ìgbàgbọ́ wọn. 20 Nínú àwọn ẹni Himeneu àti Aleksanderu ; àwọn mo ti fi Satani lọ́wọ́, a kọ́ wọn wọ́n sọ̀rọ̀-òdì mọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-