Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Timotiu 2

Àwọn ̀kọ́ lórí ìsìn

1 Nítorí náà mo gbà yín níyànjú ṣáájú ohun gbogbo, a máa bẹ̀bẹ̀, a máa gbàdúrà, a máa ṣìpẹ̀, àti a máa dúpẹ́ nítorí gbogbo ènìyàn. 2 Fún àwọn ọba, àti gbogbo àwọn ó ni ipò àṣẹ, a máa lo ayé wa àlàáfíà àti ìdákẹ́ jẹ́́ pẹ̀nínú gbogbo ìwà-bí-Ọlọ́run àti ìwà mímọ́. 3 Nítorí èyí dára, ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú Ọlọ́run Olùgbàlà wa;

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também