Publicidade

1 Timóteo 4

Àwọn ̀kọ́ fun Timotiu

1 Nísinsin yìí, èmi ń tẹnumọ́ ́ ìgbà ìkẹyìn àwọn mìíràn yóò kúrò nínú ìgbàgbọ́, wọn yóò máa fiyèsí àwọn ̀ń tannijẹ, àti ̀kọ́ àwọn ̀èṣù. 2 Nípa àgàbàgebè àwọn ń ṣèké, àwọn ọkàn tìkára wọn dàbí èyí a fi irin gbígbóná . 3 Àwọn ń dánilẹ́kun láti gbéyàwó tiwọn si ń pàṣẹ láti ka èèwọ̀ oúnjẹ ti Ọlọ́run ti fún ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀ọpẹ́ àwọn onígbàgbọ́ àti àwọn ti ó mọ òtítọ́. 4 Nítorí gbogbo ohun ti Ọlọ́run ni ó dára, ọkàn ó yẹ a kọ̀, a fi ọpẹ́ gbà á. 5 Nítorí a fi ̀rọ̀ Ọlọ́run àti àdúrà mímọ́.

6 ìwọ ń rán àwọn ará létí nǹkan wọ̀nyí, ìwọ ó jẹ́ ìránṣẹ́ rere ti Kristi Jesu, a fi ̀rọ̀ ìgbàgbọ́ àti ̀kọ́ rere bọ́, èyí ti ìwọ ti ń tẹ̀. 7 Ṣùgbọ́n kọ ̀rọ̀ asán àti ìtàn àwọn àgbà obìnrin, máa tọ́ ara rẹ ìwà-bí-Ọlọ́run. 8 Nítorí ṣíṣe eré-ìdárayá ni èrè fún ohun díẹ̀, ṣùgbọ́n ìwà-bí-Ọlọ́run ni èrè fún ohun gbogbo, ó ìlérí ti ìgbé ayé ìsinsin yìí àti ti èyí ń bọ̀. 9 Òtítọ́ ni ̀rọ̀ náà, ó yẹ fún ìtẹ́wọ́gbà gbogbo. 10 Nítorí fún èyí ni àwa ń ṣe làálàá a ń jìjàkadì, nítorí àwa ìrètí nínú Ọlọ́run alààyè, ẹni í ṣe Olùgbàlà gbogbo ènìyàn, pẹ̀lúpẹ̀ti àwọn ti ó gbàgbọ́.

11 Nǹkan wọ̀nyí ni ó máa paláṣẹ ó máa kọ́ni. 12 ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni gan ìgbà èwe rẹ; ṣùgbọ́n ìwọ jẹ́ àpẹẹrẹ fún àwọn ó gbàgbọ́, nínú ̀rọ̀, nínú ìwà híhù, nínú ìfẹ́, nínú ̀, nínú ìgbàgbọ́, nínú ìwà mímọ́. 13 Títí èmi ó fi , máa fiyèsí kíkàwé àti ìgbaniníyànjú àti ìkọ́ni. 14 ṣe àìnání ̀bùn ń bẹ lára rẹ, èyí a fi fún nípa ìsọtẹ́lẹ̀ pẹ̀ìgbọ́wọ́àwọn alàgbà.

15 Máa fiyèsí nǹkan wọ̀nyí; fi ara rẹ fún wọn pátápátá; ìlọsíwájú rẹ hàn gbangba fún gbogbo ènìyàn. 16 Máa ṣe ìtọ́ará rẹ àti ̀kọ́ rẹ; máa dúró láìyẹsẹ̀ nínú nǹkan wọ̀nyí; nítorí ṣíṣe èyí, ìwọ ó gba ara rẹ àti àwọn ti ń gbọ́ ̀rọ̀ rẹ .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-