Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kọrinti 11

24 11.24: De 25.3.Nígbà márùn-ún ni mo gba pàṣán ogójì dín ẹyọ kan lọ́wọ́ àwọn Júù. 25 11.25: Ap 16.22; 14.19.Nígbà mẹ́ta ni a fi ̀gọ̀ , ̀̀kan ṣoṣo ni a sọ òkúta, ̀̀mẹta ni ọkọ̀ ojú omi mi , ̀sán kan àti òru kan ni mo nínú ibú. 26 11.26: Ap 9.23; 14.5.ìrìnàjò nígbàkígbà, nínú ewu omi, nínú ewu àwọn ọlọ́ṣà, nínú ewu àwọn ará ìlú mi, nínú ewu àwọn aláìkọlà, nínú ewu ni ìlú, nínú ewu aginjù, nínú ewu lójú Òkun, nínú ewu láàrín àwọn èké arákùnrin. 27 11.27: 1Kọ 4.11.Nínú làálàá àti ìrora, nínú ìṣọ́ òru nígbàkígbà, nínú ebi àti òǹgbẹ, nínú àwẹ̀ nígbàkígbà, nínú òtútù àti ìhòhò.

Veja também