Publicidade

2 Coríntios 12

7 12.7: Jb 2.6.àti nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ìṣípayá, èmi ba à gbé ara mi ga rékọjá, a ti fi ̀gún kan mi lára, ìránṣẹ́ Satani láti pọ́n mi lójú, èmi a gbéraga rékọjá. 8 Nítorí nǹkan yìí ni mo ṣe bẹ Olúwa nígbà mẹ́ta , ó e kúrò lára mi. 9 Òun fún mi , "Oore-ọ̀fẹ́ mi fún , nítorí a sọ agbára mi di pípé nínú àìlera." Nítorí náà tayọ̀tayọ̀ ni èmi ó kúkú máa fi ṣògo nínú àìlera mi, agbára Kristi máa gbé inú mi. 10 12.10: Ro 5.3; 2Kọ 6.4-5.Nítorí náà èmi inú dídùn nínú àìlera gbogbo, nínú ̀gàn gbogbo, nínú àìní gbogbo, nínú inúnibíni gbogbo, nínú wàhálà gbogbo nítorí Kristi. Nítorí nígbà mo jẹ́ aláìlera, nígbà náà ni mo di alágbára.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-