Publicidade

2 Coríntios 7

1 Nítorí náà, ̀yin olùfẹ́, a ti àwọn ìlérí wọ̀nyí, jẹ́ a wẹ ara mọ́ kúrò nínú gbogbo ̀gbin ti ara àti ti ̀, a sọ ìwà mímọ́ pípé nínú ìbẹ̀Ọlọ́run.

Ayọ̀ Paulu

2 gbà tọkàntọkàn; a fi ibi ṣe ẹnikẹ́ni, a ba ẹnikẹ́ni jẹ́, a rẹ́ ẹnikẹ́ni jẹ. 3 Èmi sọ èyí láti a yín lẹ́bi; nítorí mo ṣáájú , ̀yin nínú ọkàn wa a jùmọ̀ , àti a jùmọ̀ láààyè. 4 Mo ìgboyà ńlá láti yín sọ̀rọ̀; ìṣògo lórí yín pọ̀; mo kún fún ìtùnú, mo ń yọ̀ rékọjá nínú gbogbo ìpọ́njú wa.

5 Nítorí nígbà àwa tilẹ̀ Makedonia, ara balẹ̀, ṣùgbọ́n a ń pọ́n lójú níhà gbogbo, ìjà ń bẹ lóde, ̀ń bẹ nínú. 6 Ṣùgbọ́n ẹni ń tu àwọn onírẹ̀lẹ̀ nínú, àní Ọlọ́run, ó nínú nípa dídé Titu , 7 í i ṣe nípa dídé rẹ̀ nìkan ṣùgbọ́n nípa ìtùnú náà pẹ̀ti ú nínú, nígbà ó ròyìn fún wa ìfẹ́ àtọkànwá yín, ìbànújẹ́ yín, àti ìtara yín fún mi; bẹ́̀ mo túbọ̀ yọ̀.

8 Nítorí , mo tilẹ̀ ba inú yín jẹ́ nípa ìwé mo kọ èmi kábámọ̀ mọ́, mo tilẹ̀ ti kábámọ̀ tẹ́lẹ̀ ; nítorí mo wòye ìwé mi yín banújẹ́, ó tilẹ̀ jẹ́ fún ìgbà díẹ̀. 9 Èmi yọ̀ nísinsin yìí, í ṣe nítorí a inú yín bàjẹ́, ṣùgbọ́n nítorí a inú yín bàjẹ́ ìrònúpìwàdà: nítorí ti a inú yín bàjẹ́ ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run, ̀yin ṣe ti ipasẹ̀ wa pàdánù ohunkóhun. 10 Nítorí ìbànújẹ́ ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run máa ṣiṣẹ́ ìrònúpìwàdà ìgbàlà í àbámọ̀ , ṣùgbọ́n ìbànújẹ́ ti ayé a máa ṣiṣẹ́ ikú. 11 Kíyèsi i, nítorí ohun kan náà yìí a yin banújẹ́ fún ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run, irú ìmúraṣíṣẹ́ ó jáde nínú yín, wíwẹ ara yín mọ́ ń kọ́, ìbànújẹ́ ń kọ́, ìpayà ń kọ́, ìfojúṣọ́ń kọ́, ìtara ń kọ́, ìjẹ́ni-níyà ń kọ́. Nínú ohun àmì kọ̀̀kan yìí ni ̀yin ti fi ara yín hàn aláìlẹ́bi nínú ̀ràn náà. 12 Nítorí náà, mo tilẹ̀ kọ̀yín, èmi kọ ́ nítorí ẹni ó ṣe ohun búburú náà tàbí nítorí ẹni ti a fi ohun búburú náà ṣe, ṣùgbọ́n àníyàn yín nítorí farahàn níwájú Ọlọ́run. 13 Nítorí náà, a fi ìtùnú yín nínú.

Àti nínú ìtùnú wa, a yọ̀ gidigidi nítorí Titu ayọ̀, nítorí láti ̀dọ̀ gbogbo yín ni a ti tu ̀rẹ̀ lára. 14 mo tilẹ̀ ti lérí ohunkóhun fún ún nítorí yín, a dójútì ; ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ àwa ti sọ ohun gbogbo fún yín òtítọ́, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ìlérí níwájú Titu jásí òtítọ́. 15 Ọkàn rẹ̀ gidigidi yín, òun ti ń rántí ìgbọ́ràn gbogbo yín, ti fi ìbẹ̀àti ìwárìrì tẹ́wọ́gbà á. 16 Mo yọ̀ nítorí ohun gbogbo, mo ìgbẹ́kẹ̀nínú yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-