Publicidade

2 Coríntios 9

1 Nísinsin yìí, nípa ti ìpín fún ni fún àwọn ènìyàn mímọ́, tún yẹ mọ́ fún mi láti kọ̀yin ju bẹ́̀ lọ. 2 Nítorí mo mọ ìtara láti ṣe ìrànlọ́wọ́ yín, èyí mo ti ṣògo fún àwọn ará Makedonia nítorí yín, , àwọn ara Akaia ti múra tan níwọ̀n ọdún kan ó kọjá ìtara yín ti ̀pọ̀lọpọ̀ sókè. 3 Ṣùgbọ́n mo ti rán àwọn arákùnrin, ìṣògo wa nítorí yín ṣe jásí asán ti ̀ràn yìí; gẹ́gẹ́ ti , ̀yin múra tẹ́lẹ̀. 4 ó ba à jẹ́ , àwọn nínú ara Makedonia mi , wọ́n yín àìmúra sílẹ̀, ojú a í ṣe ̀yin, ti ìgbẹ́kẹ̀yìí. 5 Nítorí náà ni mo ṣe ó yẹ láti gba àwọn arákùnrin níyànjú, wọn kọ́kọ́ tọ̀ yín , múra ̀bùn yín, ti ṣe ìlérí tẹ́lẹ̀ sílẹ̀, ó ti lẹ́bi ̀bùn gidi, ó ṣe dàbí ohun ti a fi ìkùnsínú ṣe.

Ìfúnrúgbìn tọkàntọkàn

6 Ṣùgbọ́n èyí ni mo , ẹni ó fúnrúgbìn kín ún, kín ún ni yóò ; ẹni ó fúnrúgbìn púpọ̀, púpọ̀ ni yóò . 7 olúkúlùkù ènìyàn ṣe gẹ́gẹ́ ó ti pinnu ọkàn rẹ̀; í ṣe àfi ìkùnsínú ṣe, tàbí ti àìgbọdọ̀ ṣe; nítorí Ọlọ́run fẹ́ onínúdídùn ọlọ́rẹ. 8 Ọlọ́run gbogbo oore-ọ̀fẹ́ máa i fún yín; ̀yin ó ànító ohun gbogbo, nígbà gbogbo, máa pọ̀ i iṣẹ́ rere gbogbo. 9 Gẹ́gẹ́ a ti kọ́ :

"Ó fọ́nká; ó ti fi fún àwọn tálákà,

òdodo rẹ̀ dúró láéláé."

10 Ǹjẹ́ ẹni ń fi irúgbìn fún afúnrúgbìn, àti àkàrà fún oúnjẹ, yóò fi irúgbìn fún un yín, yóò sọ ́ di púpọ̀, yóò èso òdodo yín i. 11 Bẹ́̀ ni a ó sọ yín di ọlọ́rọ̀ nínú ohun gbogbo, fún ìlawọ́ yín gbogbo ń ṣiṣẹ́ ọpẹ́ Ọlọ́run nípa wa.

12 Nítorí iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìsìn yìí kún ìwọ̀n àìní àwọn ènìyàn mímọ́ nìkan, ṣùgbọ́n ó túbọ̀ pọ̀ i nípa ̀pọ̀lọpọ̀ ọpẹ́ Ọlọ́run. 13 Nítorí ìdúró yin lábẹ́ ìdánwò iṣẹ́ ìsìn yìí, wọn yóò yin Ọlọ́run lógo fún ìgbọ́ràn yín gbígba ìyìnrere Kristi àti nípa ìlawọ́ ìdáwó yín fún wọn àti fún gbogbo ènìyàn. 14 Àti nínú àdúrà fún un yín, ọkàn wọn ń ṣe àfẹ́yín nítorí ̀pọ̀ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run ti ń bẹ nínú yín. 15 Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run nítorí aláìlèfẹnusọ ̀bùn rẹ̀!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-