Publicidade

2 João 1

1 Alàgbà,

àyànfẹ́ obìnrin ọlọ́àti àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn mo fẹ́ òtítọ́, í í ṣe èmi nìkan, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ó mọ òtítọ́ pẹ̀; 2 nítorí òtítọ́ ń gbé inú wa, yóò wa gbé títí:

3 Oore-ọ̀fẹ́, àánú, àti àlàáfíà, láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, àti láti ̀dọ̀ Jesu Kristi, Ọmọ Baba, yóò pẹ̀wa nínú òtítọ́ àti nínú ìfẹ́.

4 Mo yọ̀ gidigidi mo nínú àwọn ọmọ rẹ ń rìn nínú òtítọ́, gẹ́gẹ́ Baba ti pa àṣẹ fún wa. 5 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, mo bẹ̀ ́, obìnrin ọlọ́, í ṣe ẹni èmi ń kọ̀òfin tuntun kan , ṣe èyí ti àwa àtètèkọ́ṣe, àwa fẹ́ràn ara wa. 6 Èyí ni ìfẹ́, , àwa máa rin nípa òfin rẹ̀, èyí ni òfin náà, àní ti gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe, , ̀yin rìn nínú rẹ̀.

7 Nítorí ẹlẹ́tàn púpọ̀ ti jáde wa sínú ayé, àwọn jẹ́wọ́ Jesu Kristi nínú ara. Èyí ni ẹlẹ́tàn àti aṣòdì Kristi. 8 kíyèsára yín, ba à sọ iṣẹ́ ṣe , ṣùgbọ́n ̀yin èrè kíkún gbà. 9 Olúkúlùkù ẹni ó ń òfin si dúró nínú ̀kọ́ Kristi, mọ Ọlọ́run. Ẹni ó dúró nínú ̀kọ́, òun ni ó mọ Baba àti Ọmọ. 10 ẹnikẹ́ni tọ̀ yín , mu ̀kọ́ yìí , ṣe gbà á ilé, ṣe i ààbọ̀. 11 Nítorí ẹni ó ààbọ̀, ó ọwọ́ nínú iṣẹ́ búburú rẹ̀.

12 mo tilẹ̀ ohun púpọ̀ láti ṣe alábápín pẹ̀yín, síbẹ̀ èmi fẹ́ lo ìwé ìkọ̀àti jẹ́ìkọ̀. Ṣùgbọ́n èmi ìrètí láti tọ̀ yín àti láti a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú, ayọ̀ yín à le è kún.

13 Àwọn ọmọ arábìnrin rẹ àyànfẹ́ .

Veja também

Publicidade
2 João
Ver todos os capítulos de 2 João
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-