Publicidade

2 Timóteo 2

1 Nítorí náà ìwọ ọmọ mi, jẹ́ alágbára nínú oore-ọ̀fẹ́ ti ń bẹ nínú Kristi Jesu. 2 Àwọn ohun ti ìwọ ti gbọ́ lọ́dọ̀ mi níwájú ẹlẹ́rìí púpọ̀, àwọn náà ni ìwọ fi àwọn olóòtítọ́ ènìyàn lọ́wọ́, àwọn ti yóò máa kọ́ àwọn ẹlòmíràn pẹ̀. 3 Ṣe alábápín pẹ̀mi nínú ìpọ́njú, ọmọ-ogun rere Jesu Kristi. 4 ẹni ń jagun ti ń fi ohun ayé yìí ara rẹ̀ lọ́wọ́, ó inú ẹni ó yàn ni ọmọ-ogun dùn. 5 ̀kan náà, ẹnikẹ́ni ń díje olùdíje, a í e ládé, ṣe ó parí rẹ̀ gẹ́gẹ́ ìlànà 6 Àgbẹ̀ ti ó ń ṣe làálàá ni ó yẹ láti kọ́kọ́ mu nínú àwọn èso. 7 Ronú lórí ohun ti èmi ń sọ; nítorí Olúwa yóò fún lóye nínú ohun gbogbo.

8 Rántí Jesu Kristi, ti ó jíǹde kúrò nínú òkú, láti inú irú-ọmọ Dafidi gẹ́gẹ́ ìyìnrere mi. 9 Nínú èyí èmi ń ìpọ́njú títí inú ìdè arúfin; ṣùgbọ́n a de ̀rọ̀ Ọlọ́run. 10 Nítorí náà mo ń faradà ohun gbogbo nítorí àwọn àyànfẹ́; àwọn náà pẹ̀ìgbàlà ń bẹ nínú Kristi Jesu pẹ̀ògo ayérayé.

11 Òtítọ́ ni ̀rọ̀ náà,

bi àwa a ,

àwa yóò pẹ̀rẹ̀.

12 àwa faradà,

àwa ó a jẹ ọba.

àwa sẹ́ ,

òun náà yóò sẹ́ wa.

13 àwa gbàgbọ́,

òun dúró ni olóòtítọ́,

nítorí òun sẹ́ ara rẹ̀.

Òṣìṣẹ́ Ọlọ́run yàn

14 Nǹkan wọ̀nyí ni ki ó máa rán wọn létí. Máa kìlọ̀ fún wọn níwájú Olúwa , ki wọn ó yẹra kúrò nínú jíjiyàn ̀rọ̀ léèrè, ṣe ìparun fún àwọn ń gbọ́. 15 Ṣaápọn láti fi ara rẹ̀ hàn níwájú Ọlọ́run bi ẹni ó yege àti òṣìṣẹ́ láti tijú, ó ń pín ̀rọ̀ òtítọ́ ó ti yẹ. 16 kúrò nínú ̀rọ̀ asán, nítorí tiwọn máa síwájú nínú àìwà-bí-Ọlọ́run. 17 ̀rọ̀ wọn yóò máa fẹ́ egbò kíkẹ̀; nínú àwọn ẹni Himeneu àti Filetu ; 18 àwọn ẹni ó ti ṣìnà kúrò nínú òtítọ́, ń àjíǹde ti kọjá ; wọ́n ń bi ìgbàgbọ́ àwọn mìíràn ṣubú. 19 Ṣùgbọ́n ìpìlẹ̀ Ọlọ́run ó dájú dúró ṣinṣin, ó èdìdì yìí, , "Olúwa mọ àwọn í ṣe tirẹ̀." Àti pẹ̀, "olúkúlùkù ẹni ń orúkọ Olúwa kúrò nínú àìṣòdodo."

20 Ṣùgbọ́n nínú ilé ńlá, í ṣe kìkì ohun èlò wúrà àti ti fàdákà nìkan ni ń bẹ, ṣùgbọ́n ti igi àti amọ̀ pẹ̀; àti òmíràn ọlá, àti òmíràn àìlọ́. 21 ẹnikẹ́ni wẹ ara rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ìwọ̀nyí, òun yóò jẹ́ ohun èlò ọlá, a sọ́tọ̀, ó yẹ fún ìlò baálé, a ti pèsè sílẹ̀ fún iṣẹ́ rere gbogbo.

22 Máa fún ìfẹ́kúfẹ̀́ èwe, máa lépa òdodo, ìgbàgbọ́, ìfẹ́, àlàáfíà, pẹ̀àwọn ń pe Olúwa láti inú ọkàn funfun . 23 Ìbéèrè òmùgọ̀ àti aláìní ̀kọ́ nínú ni o kọ̀, o ti mọ̀ pe wọn máa ìjà sílẹ̀. 24 Ìránṣẹ́, Olúwa gbọdọ̀ ; ṣe ó jẹ́ ẹni pẹ̀lẹ́ ènìyàn gbogbo ẹni ó kọ́ni, àti onísùúrù. 25 Ẹni yóò máa kọ́ àwọn alátakò pẹ̀ìwà tútù, ìrètí Ọlọ́run fún wọn ìrònúpìwàdà ìmọ̀ òtítọ́, 26 wọn ó bọ́ kúrò nínú ìdẹ̀kùn èṣù, lẹ́yìn ìgbà ó ti wọn láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
2 Timóteo
Ver todos os capítulos de 2 Timóteo
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-