Publicidade

Apocalipse 12

Obìnrin kan àti dragoni

1 Àmì ńlá kan hàn ni ̀run; obìnrin kan a fi oòrùn wọ̀ aṣọ, òṣùpá ń bẹ lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, adé oníràwọ̀ méjìlá ń bẹ lórí rẹ̀. 2 12.2: Mt 4.10.Ó lóyún, ó kígbe ni ìrọbí, ó ni ìrora àti bímọ. 3 12.3: Da 7.7.Àmì mìíràn hàn ̀run; kíyèsi i, dragoni pupa ńlá kan, ó orí méje àti ìwo mẹ́wàá, àti adé méje orí rẹ̀. 4 12.4: Da 8.10.Ìrù rẹ̀ wọ́ ìdámẹ́ta àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run, ó wọ́n ilẹ̀ ayé, dragoni náà dúró níwájú obìnrin náà ó fẹ́ bímọ, nígbà o i, òun pa ọmọ rẹ̀ jẹ. 5 12.5: Isa 66.7; Sm 2.9.Ó bi ọmọkùnrin kan yóò fi ̀irin ṣe àkóso gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, a gba ọmọ rẹ̀ lọ sókè ̀dọ̀ Ọlọ́run, àti orí ìtẹ́ rẹ̀. 6 Obìnrin náà sálọ aginjù, níbi a gbé ti pèsè ààyè sílẹ̀ é láti ọwọ́ Ọlọ́run , wọ́n máa bọ́ níbẹ̀ ẹgbẹ̀ọjọ́ ó ọgọ́ta (1,260).

7 12.7: Da 10.13. Ogun ń bẹ ̀run: Mikaeli àti àwọn angẹli rẹ̀ dragoni náà jagun; dragoni jagun àti àwọn angẹli rẹ̀. 8 Wọ́n ṣẹ́gun; bẹ́̀ ni a ipò wọn mọ́ ni ̀run. 9 12.9: Gẹ 3.1,14-15; Sk 3.1.A dragoni ńlá náà jáde, ejò láéláé , a ń ni Èṣù, àti Satani, ń tan gbogbo ayé jẹ: a e ilẹ̀ ayé, a àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀rẹ̀.

10 12.10: Jb 1.9-11. Mo gbọ́ ohùn ńlá ̀run, :

"Nígbà yìí ni ìgbàlà , àti agbára, àti ìjọba Ọlọ́run ,

àti ọlá àti Kristi rẹ̀.

Nítorí a le olùfisùn àwọn arákùnrin wa jáde,

o ń fi wọ́n sùn níwájú Ọlọ́run wa lọ́sàn án àti lóru.

11 Wọ́n ti ṣẹ́gun rẹ̀

nítorí ̀jẹ̀ ̀dọ́-àgùntàn náà,

àti nítorí ̀rọ̀ ̀wọn,

wọn fẹ́ràn ̀wọn

àní títí ikú.

12 12.12: Isa 44.23; 49.13. Nítorí náà máa yọ̀, ̀yin ̀run,

àti ̀yin ń gbé inú wọn.

Ègbé ni fún ayé àti Òkun;

nítorí èṣù sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín ìbínú ńlá,

nítorí ó mọ̀ ìgbà kúkúrú ni òun ."

13 Nígbà dragoni náà a òun lọ ilẹ̀ ayé, ó ṣe inúnibíni obìnrin ó ọmọkùnrin náà. 14 12.14: Da 7.25; 12.7.A fi apá ìyẹ́ méjì idì ńlá náà fún obìnrin náà, ó lọ aginjù, ipò rẹ̀, níbi a ó gbe bọ fún àkókò kan àti fún àwọn àkókò, àti fún ìdajì àkókò kúrò lọ́dọ̀ ejò náà. 15 Ejò náà tu omi jáde láti ẹnu rẹ̀ odò ńlá sẹ́yìn obìnrin náà, ó fi ìṣàn omi náà gbà á lọ. 16 Ilẹ̀ ran obìnrin náà lọ́wọ́, ilẹ̀ ya ẹnu rẹ̀, ó fi ìṣàn omi náà , dragoni náà tu jáde láti ẹnu rẹ̀ . 17 Dragoni náà bínú gidigidi obìnrin náà, ó lọ àwọn irú-ọmọ rẹ̀ ìyókù jagun, wọ́n ń pa òfin Ọlọ́run mọ̀, wọn di ̀Jesu , Ó dúró lórí iyanrìn Òkun.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-