Pular para o conteúdo
Publicidade

Apocalipse 16

Àwọn ago ìbínú Ọlọ́run

1 16.1: Isa 66.6; Sm 69.24. Mo gbọ́ ohùn ńlá kan láti inú tẹmpili , ń fún àwọn angẹli, méje , "lọ, ago ìbínú Ọlọ́run wọ̀n-ọn-nì orí ayé."

2 16.2: Ek 9.10-11; De 28.35. Èkínní lọ, ó ago tirẹ̀ orílẹ̀ ayé: egbò kíkẹ̀ ó díbàjẹ́ àwọn ènìyàn ó àmì ẹranko náà, àti àwọn ń foríbalẹ̀ fún àwòrán rẹ̀.

3 16.3-4: Ek 7.17-21. Èkejì ago sínú Òkun; ó dàbí ̀jẹ̀ òkú ènìyàn, gbogbo ọkàn alààyè nínú Òkun.

4 ̀kẹta ago tirẹ̀ sínú odò, àti orísun àwọn omi; wọ́n di ̀jẹ̀. 5 Mo gbọ́ angẹli ó n :

"Olódodo ni ìwọ ninu gbogbo ìdájọ́ wọ̀nyí,

ìwọ ẹni ó n bẹ àti ó wa, Ẹni Mímọ́

nítorí ìwọ ṣe ìdájọ́ bẹ́̀.

6 16.6: Sm 79.3. Nítorí wọ́n ti ta ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ àti ti àwọn wòlíì sílẹ̀,

ìwọ fi ̀jẹ̀ fún wọn mu; èyí yìí ó yẹ wọ́n."

7 16.7: Sm 119.137. Mo gbọ́ ti pẹpẹ ń :

"Bẹ́̀ ni, Olúwa Ọlọ́run Olódùmarè,

òtítọ́ àti òdodo ìdájọ́ rẹ."

8 ̀kẹrin ago tirẹ̀ sórí oòrùn; a yọ̀ǹda fún un láti fi iná ènìyàn lára. 9 A fi ooru ńlá àwọn ènìyàn lára, wọ́n sọ̀rọ̀-òdì orúkọ Ọlọ́run, ẹni ó agbára lórí ìyọnu wọ̀nyí: wọn ronúpìwàdà láti fi ògo fún un.

10 16.10: Ek 10.21. ̀karùnún ago tirẹ̀ sórí ìtẹ́ ẹranko náà; ilẹ̀ ọba rẹ̀ ṣókùnkùn; wọ́n ń ahọ́n wọn jẹ́ nítorí ìrora. 11 Wọ́n sọ̀rọ̀-òdì Ọlọ́run ̀run nítorí ìrora wọn àti nítorí egbò wọn, wọ́n ronúpìwàdà iṣẹ́ wọn.

12 16.12: Isa 11.15-16. ̀kẹfà tu ìgò tirẹ̀ sórí odò ńlá Eufurate; omi rẹ̀ gbẹ, a pèsè ̀fún àwọn ọba láti ìlà-oòrùn . 13 16.13: 1Ọb 22.21-23; Ek 8.3.Mo àwọn ̀àìmọ́ mẹ́ta ̀pọ̀lọ́, wọ́n ti ẹnu dragoni náà àti ẹnu ẹranko náà àti ẹnu wòlíì èké náà jáde . 14 Nítorí ̀èṣù ni wọ́n, ń ṣe iṣẹ́ ìyanu, àwọn ń jáde lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba gbogbo ilẹ̀ ayé, láti gbá wọn jọ ogun ọjọ́ ńlá Ọlọ́run Olódùmarè.

15 16.15: 1Tẹ 5.2. "Kíyèsi i; ń bọ̀ bi olè, ìbùkún ni fún ẹni ń ṣọ́, ó ń pa aṣọ rẹ̀ mọ́, ó a rìn ni ìhòhò, wọn a ìtìjú rẹ̀."

16 16.16: 2Ọb 9.27. Ó gbá wọn jọ́ ibìkan a ń Amagedoni èdè Heberu.

17 16.17: Isa 66.6. Èkeje si ago tirẹ̀ ojú ̀run; ohùn ńlá kan ti inú tẹmpili jáde láti ibi ìtẹ́, , "Ó parí!" 18 16.18: Ek 19.16; Da 12.1.Mọ̀nàmọ́kọ, a gbọ́ ohùn, àrá sán, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá ṣẹ̀, irú èyí ṣẹ̀ ri láti ìgbà ènìyàn ti lórí ilẹ̀, irú ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá bẹ́̀, ó lágbára bẹ́̀. 19 Ìlú ńlá náà pín ipa mẹ́ta, àwọn orílẹ̀-èdè ṣubú: Babeli ńlá ìrántí níwájú Ọlọ́run, láti fi ago ọtí wáìnì ti ìrunú ìbínú rẹ̀ fún un. 20 Olúkúlùkù erékùṣù sálọ, a ri àwọn òkè ńlá mọ́. 21 16.21: Ek 9.23.Yìnyín ńlá, ̀kọ̀̀kan rẹ̀ tálẹ́ǹtì ìwọ̀n, bọ́ àwọn ènìyàn láti ̀run , àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀-òdì Ọlọ́run nítorí ìyọnu yìnyín náà; nítorí ìyọnu rẹ̀ náà pọ̀ gidigidi.

Veja também