Pular para o conteúdo
Publicidade

Apocalipse 4

Ìtẹ́ ̀run

1 4.1: Ek 19.16,24. Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí èmi , kíyèsi i, ìlẹ̀kùn kan ṣí sílẹ̀ ̀run, ohùn kìn-ín-ní mo gbọ́ ohùn ìpè ń mi sọ̀rọ̀, ó , "Gòkè níhìn-ín, èmi ó fi ohun yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn èyí hàn ́." 2 4.2: El 1.26-28.Lójúkan náà, mo nínú ̀, kíyèsi i, a tẹ́ ìtẹ́ kan ̀run, ẹnìkan jókòó lórí ìtẹ́ náà. 3 Ẹni ó jókòó náà dàbí òkúta jasperi àti kaneliani lójú. Ni àyíká ìtẹ́ náà ni òṣùmàrè kan ó dàbí òkúta emeradi lójú. 4 ìtẹ́ náà ni ìtẹ́ mẹ́rìnlélógún mìíràn; àti lórí àwọn ìtẹ́ náà mo àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún jókòó, a wọ̀ ni aṣọ àlà; adé wúrà ni orí wọn. 5 4.5: Ek 19.16; Sk 4.2.Àti láti ibi ìtẹ́ náà ni ìró mọ̀nàmọ́àti ohùn àti àrá ti jáde : níwájú ìtẹ́ náà ni fìtílà iná méje ń tàn, èyí ń ṣe ̀méje ti Ọlọ́run. 6 4.6: El 1.5,18.Àti láti ibi ìtẹ́ náà ni òkun bi dígí o dàbí kristali.

Àti ìtẹ́ náà ̀gbẹ́ kọ̀̀kan ni ̀alààyè mẹ́rin ó kún fún ojú níwájú àti lẹ́yìn wọn. 7 4.7: El 1.10.̀kìn-ín-ní dàbí kìnnìún, ̀kejì si dàbí ọmọ màlúù, ̀kẹta ni ojú bi ti ènìyàn, ̀kẹrin dàbí idì ń . 8 4.8: Isa 6.2-3.Àwọn ̀alààyè mẹ́rin náà, olúkúlùkù wọn ni ìyẹ́ mẹ́, kún fún ojú yíká ara àti nínú; wọn sinmi lọ́sàn àti lóru, láti :

" Mímọ́, mímọ́, mímọ́,

Olúwa Ọlọ́run Olódùmarè,

ó ti , ó ń bẹ, ó ń bọ̀ !"

9 4.9: Sm 47.8. Nígbà àwọn ̀alààyè náà fi ògo àti ọlá, àti ọpẹ́ fún ẹni o jókòó lórí ìtẹ́, o ń bẹ láààyè láé àti láéláé. 10 Àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún náà yóò wólẹ̀ níwájú ẹni o jókòó lórí ìtẹ́, wọn yóò tẹríba fún ẹni ń bẹ láààyè láé àti láéláé, wọn yóò fi adé wọn lélẹ̀ níwájú ìtẹ́ náà, :

11 "Olúwa àti Ọlọ́run, ìwọ ni o yẹ,

láti gba ògo àti ọlá àti agbára,

nítorí ìwọ ni o ohun gbogbo,

àti nítorí ìfẹ́ inú rẹ̀ ni

wọn fi a wọn."

Veja também