1Mo fi Febe arábìnrin wa le yin lọ́wọ́, ẹni tí ó jẹ́ díákónì nínú ìjọ tí ó wà ní Kenkerea.
2Mo rọ̀ yín kí ẹ …
225 resultados encontrados
1Mo fi Febe arábìnrin wa le yin lọ́wọ́, ẹni tí ó jẹ́ díákónì nínú ìjọ tí ó wà ní Kenkerea.
2Mo rọ̀ yín kí ẹ …
5"Nítorí àwa rí ọkùnrin yìí, …
6ẹni tí ó gbìyànjú láti ba tẹmpili jẹ́.24.6 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ kan se àfikún ọ̀rọ̀ pé, ṣùgbọ́n àwa gbá a mú àwa sí fẹ́ bá a ṣe ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bí òfin wa. 7 Ṣùgbọ́n Lisia olórí ogun dé, ó fì agbára ńlá gbà á lọ́wọ́ wa, 8 ó sì pàṣẹ pé kí àwọn olùfisùn rè wá sí iwájú rẹ. Nígbà
10Ó sì ṣe bí Aaroni …
11Olúwa sọ fún Mose pé,
12"Èmi ti gbọ́ kíkùn àwọn …
1"Àyà sì fò mi sí …
2Fetísílẹ̀! Fetísílẹ̀, kí ẹ sì gbọ́ ìró ohùn rẹ̀,
3Ó ṣe ìlànà rẹ̀ ní …
1 1.1: Gẹ 1.1; 1Jh 1.1; …
2Òun ni ó sì wà pẹ̀lú Ọlọ́run ní àtètèkọ́ṣe.
31.3: Kl 1.16; 1Kọ 8.6; …
13Ìwọ ní apá agbára;
14Òdodo àti òtítọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ:
15Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn …
12Mo mọ̀ ohun tí o …
134.13: 2Kọ 12.9.Èmi le ṣe ohun gbogbo nínú Kristi ẹni ti ń fi agbára fún mi.
14Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ṣeun gidigidi ní …
41.4: Ga 2.20; 1Tm 2.6.ẹni …
51.5: Ro 16.27.ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín.
6Ó yà mi lẹ́nu pé ẹ tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni tí ó pè yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, sí ìyìnrere mìíràn.
7Ọgbọ́n ga ju fún aṣiwèrè
8Ẹni tí ń pète ibi
9Ète òmùgọ̀ ènìyàn jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀,
5àti ọ̀rọ̀ àríyànjiyàn àwọn ènìyàn …
6Ṣùgbọ́n ìwà-bí-Ọlọ́run pẹ̀lú ìtẹ́lọ́rùn èrè ńlá ni.
7Nítorí a kò mú ohun …
3Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe …
4Nígbà tí Olórí Olùṣọ́-àgùntàn bá sì fi ara hàn, ẹ̀yin ó gba adé ògo ti kì í sá.
5 5.5: Òw 3.34. Bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú, …
4kí wọ́n má sì ṣe …
5Ète àṣẹ náà ni ìfẹ́ ti ń jáde wá láti inú ọkàn mímọ́ àti ẹ̀rí ọkàn rere àti ìgbàgbọ́ àìṣẹ̀tàn.
6Àwọn ẹlòmíràn ti yapa kúrò …
1Ǹjẹ́ àǹfààní wo ní Júù ní? Tàbí kín ni èrè ilà kíkọ?
23.2: Sm 147.19; Ro 9.4.Púpọ̀ …
8Ọlọ́run, tí ó jẹ́ olùmọ̀-ọkàn, …
9Kò sí fi ìyàtọ̀ sí àárín àwa àti àwọn, ó ń fi ìgbàgbọ́ wẹ̀ wọ́n lọ́kàn mọ́.
10Ǹjẹ́ nítorí náà èéṣe tí …
1Benjamini jẹ́ baba:
2Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
3Àwọn ọmọ Bela ni,
1Ẹ máa lépa ìfẹ́, ki ẹ sí máa fi ìtara ṣàfẹ́rí ẹ̀bùn tí í ṣe ti Ẹ̀mí, ṣùgbọ́n ki ẹ kúkú lé máa sọtẹ́lẹ̀.
2Nítorí ẹni tí ń sọ̀rọ̀ …
3Ẹ wó àwọn pẹpẹ wọn, …
4Ẹ kò gbọdọ̀ sin Olúwa Ọlọ́run yín bí i tiwọn.
5Ṣùgbọ́n ẹ wá ibi tí …
6Ẹ gbọ́ àwíyé mi nísinsin …
7Ẹ̀yin fẹ́ sọ ìsọkúsọ fún Ọlọ́run?
8Ẹ̀yin fẹ́ ṣe ojúsàájú rẹ̀?
716.7: Ap 18.21.Nítorí èmi kò …
816.8: Ap 18.19.Ṣùgbọ́n èmi yóò dúró ni Efesu títí dí Pentikosti.
916.9: Ap 19.9.Nítorí pé ìlẹ̀kùn …
9" ‘Èyí yìí ni Olúwa …
10Kí ẹ̀yin kì ó lo òsùwọ̀n tó tọ́ àti efa títọ́ àti bati títọ́.
11Efa àti bati gbọdọ̀ jẹ́ bákan náà, kí bati tí ó gba ìdámẹ́wàá homeri, àti efa ìdámẹ́wàá homeri: Homeri ni kí ó jẹ́ òsùwọ̀n tí ẹ̀yin yóò lò fún méjèèjì.