Publicidade

Resultados da busca por "fé"

225 resultados encontrados

1Mo fi Febe arábìnrin wa le yin lọ́wọ́, ẹni tí ó jẹ́ díákónì nínú ìjọ tí ó wà ní Kenkerea.

2Mo rọ̀ yín kí ẹ

5"Nítorí àwa rí ọkùnrin yìí,

6ẹni tí ó gbìyànjú láti ba tẹmpili jẹ́.24.6 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ kan se àfikún ọ̀rọ̀ pé, ṣùgbọ́n àwa gbá a mú àwa sí fẹ́ bá a ṣe ẹjọ́ gẹ́gẹ́ bí òfin wa. 7 Ṣùgbọ́n Lisia olórí ogun dé, ó fì agbára ńlá gbà á lọ́wọ́ wa, 8 ó sì pàṣẹ pé kí àwọn olùfisùn rè wá sí iwájú rẹ. Nígbà

10Ó sì ṣe bí Aaroni

11Olúwa sọ fún Mose pé,

12"Èmi ti gbọ́ kíkùn àwọn

1"Àyà sì fò mi sí

2Fetísílẹ̀! Fetísílẹ̀, kí ẹ sì gbọ́ ìró ohùn rẹ̀,

3Ó ṣe ìlànà rẹ̀ ní

1 1.1: Gẹ 1.1; 1Jh 1.1;

2Òun ni ó sì wà pẹ̀lú Ọlọ́run ní àtètèkọ́ṣe.

31.3: Kl 1.16; 1Kọ 8.6;

13Ìwọ ní apá agbára;

14Òdodo àti òtítọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ:

15Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn

12Mo mọ̀ ohun tí o

134.13: 2Kọ 12.9.Èmi le ṣe ohun gbogbo nínú Kristi ẹni ti ń fi agbára fún mi.

14Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ṣeun gidigidi ní

41.4: Ga 2.20; 1Tm 2.6.ẹni

51.5: Ro 16.27.ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín.

6Ó yà mi lẹ́nu pé ẹ tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni tí ó pè yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, sí ìyìnrere mìíràn.

7Ọgbọ́n ga ju fún aṣiwèrè

8Ẹni tí ń pète ibi

9Ète òmùgọ̀ ènìyàn jẹ́ ẹ̀ṣẹ̀,

5àti ọ̀rọ̀ àríyànjiyàn àwọn ènìyàn

6Ṣùgbọ́n ìwà-bí-Ọlọ́run pẹ̀lú ìtẹ́lọ́rùn èrè ńlá ni.

7Nítorí a kò mú ohun

3Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe

4Nígbà tí Olórí Olùṣọ́-àgùntàn bá sì fi ara hàn, ẹ̀yin ó gba adé ògo ti kì í sá.

5 5.5: Òw 3.34. Bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú,

4kí wọ́n má sì ṣe

5Ète àṣẹ náà ni ìfẹ́ ti ń jáde wá láti inú ọkàn mímọ́ àti ẹ̀rí ọkàn rere àti ìgbàgbọ́ àìṣẹ̀tàn.

6Àwọn ẹlòmíràn ti yapa kúrò

1Ǹjẹ́ àǹfààní wo ní Júù ní? Tàbí kín ni èrè ilà kíkọ?

23.2: Sm 147.19; Ro 9.4.Púpọ̀

8Ọlọ́run, tí ó jẹ́ olùmọ̀-ọkàn,

9Kò sí fi ìyàtọ̀ sí àárín àwa àti àwọn, ó ń fi ìgbàgbọ́ wẹ̀ wọ́n lọ́kàn mọ́.

10Ǹjẹ́ nítorí náà èéṣe tí

1Benjamini jẹ́ baba:

2Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.

3Àwọn ọmọ Bela ni,

1Ẹ máa lépa ìfẹ́, ki ẹ sí máa fi ìtara ṣàfẹ́rí ẹ̀bùn tí í ṣe ti Ẹ̀mí, ṣùgbọ́n ki ẹ kúkú lé máa sọtẹ́lẹ̀.

2Nítorí ẹni tí ń sọ̀rọ̀

3Ẹ wó àwọn pẹpẹ wọn,

4Ẹ kò gbọdọ̀ sin Olúwa Ọlọ́run yín bí i tiwọn.

5Ṣùgbọ́n ẹ wá ibi tí

6Ẹ gbọ́ àwíyé mi nísinsin

7Ẹ̀yin fẹ́ sọ ìsọkúsọ fún Ọlọ́run?

8Ẹ̀yin fẹ́ ṣe ojúsàájú rẹ̀?

716.7: Ap 18.21.Nítorí èmi kò

816.8: Ap 18.19.Ṣùgbọ́n èmi yóò dúró ni Efesu títí dí Pentikosti.

916.9: Ap 19.9.Nítorí pé ìlẹ̀kùn

9" ‘Èyí yìí ni Olúwa

10Kí ẹ̀yin kì ó lo òsùwọ̀n tó tọ́ àti efa títọ́ àti bati títọ́.

11Efa àti bati gbọdọ̀ jẹ́ bákan náà, kí bati tí ó gba ìdámẹ́wàá homeri, àti efa ìdámẹ́wàá homeri: Homeri ni kí ó jẹ́ òsùwọ̀n tí ẹ̀yin yóò lò fún méjèèjì.

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-20_17-16-08-