Publicidade

Colossenses 1

1 Paulu, aposteli Jesu Kristi nípa ìfẹ́ Ọlọ́run àti Timotiu arákùnrin wa,

2 àwọn ẹni mímọ́ àti àwọn arákùnrin àti arábìnrin nínú Kristi wọ́n ń gbé ìlú Kolose:

Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún un yín láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa.

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

3 Nígbàkígbà a ń gbàdúrà fún un yín ni a máa ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run Baba Olúwa wa Jesu Kristi. 4 Nítorí a ti gbúròó ìgbàgbọ́ yín nínú Jesu Kristi, àti ti ṣe fẹ́ràn gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́. 5 Ìgbàgbọ́ àti ìfẹ́ ń sàn nínú ìrètí a gbé pamọ́ fún un yín ̀run èyí ̀yin ti gbọ́ tẹ́lẹ̀ nínú ̀rọ̀ òtítọ́ ìyìnrere náà, 6 èyí ó ti ̀dọ̀ yín. Káàkiri àgbáyé ni ìyìnrere yìí ń so èso ó ń dàgbà, gẹ́gẹ́ ó ti ń ṣe láàrín yín láti ọjọ́ náà ti gbọ́ , ìmọ̀ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run nínú gbogbo òtítọ́ rẹ̀. 7 ̀yin ti kọ́ lọ́dọ̀ Epafira, ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ wa olùfẹ́, ẹni ó jẹ́ olóòtítọ́ ìránṣẹ́ Kristi ipò wa. 8 Ẹni ti ó sọ fún wa nípa ìfẹ́ yín nínú ̀.

9 Nítorí ìdí èyí, láti ọjọ́ a ti gbọ́ nípa yín, a sinmi láti máa gbàdúrà fún yin, a ń gbàdúrà Ọlọ́run fi ìmọ̀ ìfẹ́ rẹ̀ kún yín nípasẹ̀ ọgbọ́n àti òye gbogbo ń ṣe ti ̀. 10 Àwa ń gbàdúrà yìí gbé irú ìgbé ayé yẹ fún Olúwa máa wu ú gbogbo ̀, máa so èso rere gbogbo, máa dàgbà nínú ìmọ̀ Ọlọ́run, 11 a fi ipa gbogbo sọ yín di alágbára gẹ́gẹ́ agbára rẹ̀ àti ògo rẹ̀, ó ṣe é ṣe fún un yín láti máa tẹ̀síwájú nínú sùúrù àti ìpamọ́ra pẹ̀ayọ̀. 12 a máa dúpẹ́ nígbà gbogbo lọ́wọ́ Baba, ẹni ó yín láti jẹ́ alábápín nínú ogún àwọn ẹni mímọ́ nínú ìjọba ìmọ́lẹ̀. 13 Nítorí ó ti wa gbà kúrò nínú agbára òkùnkùn ó wa ìjọba Ọmọ ó fẹ́ràn. 14 Nínú ẹni a ìràpadà, àti ìdáríjì ̀ṣẹ̀.

Títóbi Kristi

15 Kristi ni àwòrán Ọlọ́run a le , àkọ́gbogbo ̀. 16 Nítorí nípa rẹ̀ a ohun gbogbo: àwọn ohun ń bẹ ̀run àti ayé, ohun a àti èyí a , wọn ìbá ṣe ìtẹ́, tàbí agbára, tàbí àṣẹ, nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ohun gbogbo àti fún un. 17 Ó ti ṣáájú ohunkóhun , nínú rẹ̀ ni a so ohun gbogbo papọ̀ ṣọ̀kan. 18 Òun ni orí fún ara, èyí í ṣe ìjọ; òun ni ìbẹ̀rẹ̀ àti àkọ́nínú àwọn òkú, nínú ohun gbogbo òun ipò ó ga jùlọ nínú ohunkóhun. 19 Nítorí ìfẹ́ Ọlọ́run ni gbogbo ̀kúnrẹ́rẹ́ òun tìkára rẹ̀ máa gbé nínú rẹ̀. 20 Àti nípasẹ̀ rẹ̀ láti ohun gbogbo làjà àwọn nǹkan ń bẹ láyé àti èyí ń bẹ ̀run, nípa mímú àlàáfíà nípasẹ̀ ̀jẹ̀ rẹ̀, a ta sílẹ̀ lórí igi àgbélébùú.

21 ̀yin ya ara yín nípá kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run nígbà kan , jẹ́ ̀nínú ọkàn yín nítorí ìwà búburú yín. 22 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ó ti yín làjà nípa ara Kristi nípa ikú láti un yín lọ iwájú rẹ̀ mímọ́, aláìlábàwọ́n àti kúrò nínú ìdálẹ́bi, 23 ̀yin dúró nínú ìgbàgbọ́ yín, fi ẹsẹ̀ múlẹ̀, dúró ṣinṣin, láláìyẹsẹ̀ kúrò nínú ìrètí ti ìyìnrere ti ̀yin ti gbọ́, èyí a ti wàásù rẹ̀ fún gbogbo ̀lábẹ́ ̀run, àti èyí ti èmi Paulu ṣe ìránṣẹ́ fún.

Iṣẹ́ Paulu ṣíṣe fún àwọn ìjọ

24 Nísinsin yìí èmi ń yọ̀ nínú ìjìyà fún un yín. Inú mi dùn, nítorí mo ń ṣe ìrànlọ́wọ́ láti jẹ ìyà ṣẹ́nínú ìyà Kristi fún ara rẹ̀, èyí ì ṣe ìjọ. 25 Nínú èyí a fi ṣe ìránṣẹ́ fún gẹ́gẹ́ iṣẹ́ ìríjú Ọlọ́run a fi fún mi fún yín láti ̀rọ̀ Ọlọ́run ṣẹ. 26 Ó ti pa àṣírí ìjìnlẹ̀ yìí mọ́ fún ayérayé àti láti ìrandíran. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, gẹ́gẹ́ ìfẹ́ ọkàn rẹ̀, ó ti fihàn fún àwọn ẹni mímọ́. 27 Àwọn ẹni Ọlọ́run yàn láti fihàn láàrín àwọn aláìkọlà nípa ̀rọ̀ ògo ohun ìjìnlẹ̀ yìí, èyí í ṣe Kristi ìrètí ògo nínú yín.

28 Àwa ń wàásù rẹ̀, a ń gbani níyànjú a ń kọ olúkúlùkù ènìyàn ọgbọ́n gbogbo, a olúkúlùkù ̀dọ̀ Ọlọ́run pípé nínú Kristi. 29 èyí ni èmi ń ṣe làálàá, ti mo ń làkàkà pẹ̀gbogbo agbára rẹ̀, èyí ń ṣiṣẹ́ nínú mi.

Veja também

Publicidade
Colossenses
Ver todos os capítulos de Colossenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-