Publicidade

Daniel 1

̀kọ́ Daniẹli Babeli

1 ọdún kẹta Jehoiakimu jẹ ọba Juda, Nebukadnessari ọba Babeli Jerusalẹmu, ó kọlù ú pẹ̀àwọn ọmọ-ogun rẹ̀. 2 Olúwa fa Jehoiakimu ọba Juda e lọ́wọ́, pẹ̀àwọn ohun èlò ilé Ọlọ́run. Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó lọ ilé òrìṣà Babeli, inú ilé ìṣúra òrìṣà rẹ̀.

3 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Aṣipenasi, olórí àwọn ìwẹ̀ààfin rẹ̀ , ó nínú àwọn ọmọ Israẹli wọ́n láti ìdílé ọba àti lára àwọn ó láti ilé ọlá. 4 Àwọn ̀dọ́mọkùnrin àbùkù ara, wọ́n rẹwà, wọ́n fi ìfẹ́ ̀kọ́ hàn, wọ́n ìmọ̀, òye tètè ń àti àwọn ó kún ojú òsùwọ̀n láti ṣiṣẹ́ ààfin ọba ó kọ́ wọ́n èdè àti onírúurú ̀kọ́ ìwé ti àwọn Babeli. 5 Ọba pèsè oúnjẹ ojoojúmọ́ àti wáìnì láti orí tábìlì i rẹ̀ fún wọn, ó kọ́ wọn fún ọdún mẹ́ta. Lẹ́yìn náà ni wọn yóò bẹ̀rẹ̀ í ṣiṣẹ́ fún ọba.

6 Lára àwọn wọ̀nyí ni àwọn láti Juda: Daniẹli, Hananiah, Miṣaeli àti Asariah. 7 Olórí àwọn ìwẹ̀fún wọn orúkọ tuntun: Ó fún Daniẹli Belteṣassari, ó fún Hananiah Ṣadraki, ó fún Miṣaeli Meṣaki àti Asariah Abednego.

8 Ṣùgbọ́n Daniẹli pinnu ọkàn ara rẹ̀ òun ba ara òun jẹ́ pẹ̀oúnjẹ àti wáìnì ọba, nígbà náà ni ó gba ààyè lọ́wọ́ olórí àwọn ìwẹ̀òun fẹ́ ba ara òun jẹ́ ̀yìí. 9 Ọlọ́run Daniẹli ojúrere àti àánú gbà láti ọwọ́ olórí àwọn ìwẹ̀, 10 ṣùgbọ́n olórí àwọn ìwẹ̀sọ fún Daniẹli , "Mo bẹ̀olúwa mi, ẹni o ti pèsè oúnjẹ àti ohun mímu rẹ. Báwo ni ìrísí rẹ yóò ṣe burú ti àwọn ̀dọ́mọkùnrin ẹlẹgbẹ́ ̀ rẹ lọ? Nígbà náà ni èmi yóò fi orí mi wéwu lọ́dọ̀ ọba."

11 Nígbà náà ni Daniẹli sọ fún olùṣọ́ olórí àwọn ìwẹ̀yàn lórí i Daniẹli, Hananiah, Miṣaeli àti Asariah , 12 "Jọ̀wọ́ dán àwa ìránṣẹ́ rẹ fún ọjọ́ mẹ́wàá. ṣe fún wa ohun kankan, àfi ewébẹ̀ láti jẹ àti omi láti mu. 13 Nígbà náà ni o fi ìrísí i wa ti àwọn ̀dọ́mọkùnrin wọ́n ń jẹ oúnjẹ ọba, o ṣe àwa ìránṣẹ́ rẹ ìbámu pẹ̀u o ṣe i ." 14 Bẹ́̀ ni ó gbà láti dán wọn fún ọjọ́ mẹ́wàá.

15 Lẹ́yìn ọjọ́ kẹwàá ara wọn le, wọ́n sanra ju àwọn ̀dọ́mọkùnrin wọ́n ń jẹ oúnjẹ ọba lọ. 16 Bẹ́̀ ni olùṣọ́ oúnjẹ àdídùn àti wáìnì ó yẹ wọ́n mu kúrò, ó fún wọn ewébẹ̀ dípò rẹ̀.

17 Ọlọ́run fún àwọn ̀dọ́mọkùnrin mẹ́rẹ̀̀rin wọ̀nyí ìmọ̀ àti òye nínú gbogbo onírúurú ìwé àti ̀kọ́ wọn: Daniẹli òye ìran àti àlá oríṣìíríṣìí.

18 òpin ìgbà ọba , a wọn sínú ààfin, olórí àwọn ìwẹ̀wọn síwájú ọba Nebukadnessari. 19 Ọba wọn sọ̀rọ̀, ó i ẹni ó dàbí i Daniẹli, Hananiah, Miṣaeli àti Asariah; nítorí náà wọ́n bẹ̀rẹ̀ ṣe iṣẹ́ ọba. 20 Nínú gbogbo ̀ràn ọgbọ́n àti òye ọba ń béèrè lọ́wọ́ wọn, ó i wọ́n sàn ìlọ́po mẹ́wàá ju gbogbo àwọn amòye àti ọlọ́gbọ́n ó gbogbo ìjọba rẹ̀.

21 Daniẹli níbẹ̀ títí di ọdún kìn-ín-ní ọba Kirusi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-