Publicidade

Daniel 10

Daniẹli ìran ọkùnrin kan

1 ọdún kẹta Kirusi ọba Persia, a fi ìran kan hàn Daniẹli (ẹni à ń Belteṣassari). Òtítọ́ ni ̀rọ̀ ìran náà, ó í ṣe pẹ̀àsìkò ìpọ́njú ńlá, òye ̀rọ̀ náà a nínú ìran.

2 àsìkò náà, èmi Daniẹli ṣọ̀fọ̀ fún ̀sẹ̀ mẹ́ta. 3 Èmi í jẹ oúnjẹ ó dára, èmi fi ẹran tàbí wáìnì kan ẹnu mi, bẹ́̀ ni èmi fi òróró para títí ̀sẹ̀ mẹ́ta fi kọjá.

4 ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù àkọ́kọ́, mo ti dúró etí i bèbè odò ńlá Tigirisi, 5 10.5-6: If 1.13-14; 2.18.mo wo òkè, mo ọkùnrin kan ó wọ aṣọ àlà, ̀gbẹ́ ẹni a fi wúrà Upasi dáradára àmùrè. 6 Ara rẹ̀ dàbí berili, ojú u rẹ̀ dàbí mọ̀nàmọ́, ẹyin ojú u rẹ̀ dàbí iná àtẹ̀tàn, apá àti ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí ìtànná ìmọ́lẹ̀ o kún fún idẹ, àti ohùn rẹ̀ dàbí i ti ìjọ ènìyàn púpọ̀.

7 Èmi Daniẹli, ni ẹnìkan ó ìran náà, àwọn ọkùnrin ó pẹ̀u mi, wọn i, ṣùgbọ́n ìpayà ńlá wọ́n, wọ́n sálọ wọ́n fi ara pamọ́. 8 Ó ku èmi nìkan, mo ìran ńlá yìí, ku okun kankan fún mi, ojú u mi rẹ̀wẹ̀gidigidi, n agbára mọ́. 9 Nígbà náà, ni mo gbọ́ ó ń sọ̀rọ̀, mo ṣe tẹ́sílẹ̀ i, mo sùn lọ fọnfọn, ìdojúbolẹ̀.

10 Ọwọ́ kan kàn , ó gbé mi dìde ìwárìrì lórí ọwọ́ àti eékún mi. 11 Ó sọ , "Daniẹli ẹni a yàn fẹ́ gidigidi gba ̀rọ̀ mo fẹ́ sọ yìí yẹ̀ dáradára, o dìde, nítorí a rán mi ." ó ṣe sọ èyí fún mi, mo dìde ìwárìrì.

12 Nígbà náà ni ó tẹ̀síwájú, , "ṣe bẹ̀Daniẹli. Láti ọjọ́ àkọ́kọ́ ìwọ ti fi ọkàn rẹ sílẹ̀ níwájú Ọlọ́run rẹ, a gbọ́ ̀rọ̀ rẹ, mo nítorí ̀rọ̀ náà. 13 10.13,21: If 12.7.Ṣùgbọ́n ọmọ-aládé ìjọba Persia mi dúró fún ọjọ́ mọ́kànlélógún. Nígbà náà ni Mikaeli, ̀kan lára ìjòyè àwọn ọmọ-aládé, láti ràn mi lọ́wọ́, nítorí a mi dúró níbẹ̀ pẹ̀ọba Persia. 14 ìsinsin yìí mo láti ṣàlàyé ohun yóò ṣẹlẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ ọjọ́ iwájú, nítorí ìran náà ń sọ nípa ọjọ́ iwájú."

15 ó ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí fún mi, mo dorí kodò mo dákẹ́. 16 Nígbà náà, ni ẹnìkan ó ènìyàn fi ọwọ́ kan ètè mi, mo la ẹnu mi, mo bẹ̀rẹ̀ sọ ̀rọ̀, mo sọ fún ẹni ó dúró níwájú mi, "Ìrònú mi, nítorí ìran náà, olúwa mi, n okun. 17 Ǹjẹ́ báwo ni èmi ìránṣẹ́ ̀ rẹ ṣe sọ̀rọ̀, olúwa mi? Agbára mi ti lọ, agbára káká ni mo fi ń ."

18 ̀wẹ̀, ẹnìkan ó ènìyàn fi ọwọ́ kàn , ó fún mi agbára. 19 Ó , "ṣe bẹ̀, ìwọ ọkùnrin olùfẹ́ gidigidi. Àlàáfíà ni fún , ara le, àní ara le."

Nígbà ohun mi sọ̀rọ̀, a mi lára le. "Mo , olúwa mi ó máa sọ̀rọ̀, níwọ̀n ìgbà ìwọ ti mi ara le."

20 Nígbà náà, ni ó , "Ṣé o mọ ìdí mo fi tọ̀ ́ ? Láìpẹ́ èmi yóò yípadà lọ àwọn ọmọ-aládé Persia , nígbà mo lọ àwọn ọmọ-aládé Giriki yóò ; 21 ṣùgbọ́n àkọ́kọ́, èmi yóò sọ ohun wọ́n kọ sínú ìwé òtítọ́ fún . (ẹni ó kún mi lọ́wọ́ fún nǹkan wọ̀nyí ṣe Mikaeli, ọmọ-aládé e yín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-