Pular para o conteúdo
Publicidade

Daniel 8

Daniẹli ìran àgbò kan àti òbúkọ kan

1 Nígbà ó di ọdún kẹta ìjọba Belṣassari ọba, èmi Daniẹli ìran kan èyí mo ti tẹ́lẹ̀. 2 Nínú ìran náà, mo ara mi nínú ilé ìṣọ́ Susa agbègbè ìjọba Elamu: nínú ìran náà mo lẹ́gbẹ̀́ odò Ulai. 3 Mo wo òkè mo àgbò kan ó ìwo méjì níwájú mi, ó dúró ̀gbẹ́ odò Ulai, àwọn ìwo náà gùn. Ṣùgbọ́n ̀kan gùn ju èkejì lọ, èyí ó gùn ni ó yọ jáde kẹ́yìn. 4 Mo àgbò náà ó ń kàn ìhà ìwọ̀-oòrùn, àríwá, àti gúúsù, ẹranko kankan ó le è dojúkọ ́, ẹnìkan ó le è yọ ́ kúrò lọ́wọ́ agbára rẹ̀, ó ń ṣe ó ti ú, ó di alágbára.

5 mo ṣe ń ronú nípa èyí, lójijì ni òbúkọ kan ó ìwo láàrín ojú u rẹ̀ méjèèjì jáde láti ìhà ìwọ̀-oòrùn, ó la gbogbo ayé kọjá láìfi ara kan ilẹ̀. 6 Ó tọ àgbò ó ni ìwo méjì náà , èyí mo dúró ̀gbẹ́ odò Ulai, ó dojúkọ ́ pẹ̀ìrunú ó lágbára. 7 Mo i ó fi ìtara kọlu àgbò náà, ó lu àgbò náà bolẹ̀, ó ṣẹ́ ìwo rẹ̀ méjèèjì. Àgbò náà agbára láti dojúkọ ́, Òbúkọ náà kàn án mọ́lẹ̀, ó fi ẹsẹ̀ tẹ̀ ́ mọ́lẹ̀, ṣí ẹni ó gba àgbò náà kúrò lọ́wọ́ agbára rẹ̀. 8 Òbúkọ náà di alágbára púpọ̀, ṣùgbọ́n nígbà ó góńgó, agbára rẹ̀ ru sókè, ìwo ńlá a rẹ̀ ṣẹ́ dànù, ipò o rẹ̀, ìwo mẹ́rin mìíràn , ó yọrí ìhà igun mẹ́rẹ̀̀rin ̀run.

9 Lára ̀kan nínú wọn, ìwo mìíràn yọ jáde, ó kékeré, ṣùgbọ́n ó dàgbà nínú agbára ìhà gúúsù, àti ìhà ìlà-oòrùn àti ilẹ̀ dídára. 10 8.10: If 12.4.Ó dàgbà títí ó fi kan ẹgbẹ́ ogun ̀run, ó lára àwọn ẹgbẹ́ ogun ̀run ayé ó tẹ̀ wọ́n mọ́lẹ̀, 11 ó gbé ara rẹ̀ ga gẹ́gẹ́ ọmọ-aládé ẹgbẹ́ ogun ̀run; ó ẹbọ ojoojúmọ́ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, ó gba ààyè ibi mímọ́ rẹ̀. 12 A fún un ẹgbẹ́ ogun ̀run àti ẹbọ ojoojúmọ́ nítorí ìwà ọlọ̀tẹ̀ rẹ̀, ó sọ òtítọ́ nínú gbogbo ohun ṣe.

13 8.13: Lk 21.24. Nígbà náà, ni mo gbọ́ ẹni mímọ́ ń sọ̀rọ̀, àti ẹni mímọ́ mìíràn sọ̀rọ̀ fún un , "Yóò ti pẹ́ ìran yìí yóò fi ìmúṣẹìran nípa ẹbọ ojoojúmọ́, ìṣọ̀tẹ̀ ó ìsọdahoro wa, àní láti fi ibi mímọ́ àti ogun ̀run fún ni ìtẹ̀mọ́lẹ̀?"

14 Ó sọ fún mi , "Yóò gbà ẹgbọ̀kànlá lọ́gọ́rùn-ún (2,300) alẹ́ àti òwúrọ̀; lẹ́yìn náà ni a ó tún ibi mímọ́ mímọ́."

Angẹli Gabrieli túmọ̀ ìran náà

15 Nígbà èmi Daniẹli, ń wo ìran náà, mo ń fẹ́ ó mi, ẹnìkan ó dúró níwájú mi. 16 Mo gbọ́ ohùn ènìyàn ̀gbẹ́ Ulai, ó ń "Gabrieli, sọ ìtumọ̀ ìran náà fún ọkùnrin yìí."

17 ó ṣe súnmọ́ ibi mo dúró , ̀, mo dọ̀bálẹ̀. Ó ń sọ fún mi , "Ọmọ ènìyàn, jẹ́ ó ìran náà ń sọ nípa ìgbà ìkẹyìn ni."

18 ó ṣe ń mi sọ̀rọ̀, mo ti sùn lọ fọnfọn, mo ṣe da ojú bolẹ̀. Nígbà náà ni ó fi ọwọ́ kàn , ó gbé mi dúró lórí ẹsẹ̀ mi.

19 Ó sọ , "Èmi yóò sọ ohun yóò ṣẹlẹ̀ ìkẹyìn ìgbà ìbínú, nítorí ìran náà jẹ mọ́ àkókò ohun a yàn nígbà ìkẹyìn. 20 Àgbò oníwo méjì o , òun ni ó dúró gẹ́gẹ́ àwọn ọba Media àti Persia. 21 Òbúkọ onírun náà ni ọba Giriki, ìwo ńlá ti ó láàrín ojú u rẹ̀ ni ọba àkọ́kọ́. 22 Ìwo mẹ́rin mìíràn dìde dúró dípò ̀kan ó ṣẹ́, èyí dúró gẹ́gẹ́ ìjọba mẹ́rin yóò dìde nínú orílẹ̀-èdè náà, ṣùgbọ́n wọn yóò irú agbára kan náà.

23 "ìgbà ìkẹyìn ìjọba wọn, nígbà àwọn oníwà búburú kíkún, ni ọba kan yóò dìde, ojú rẹ̀ le koko, ó mòye ̀rọ̀ àrékérekè. 24 Yóò di alágbára, ṣùgbọ́n í ṣe nípa agbára rẹ̀. Yóò máa ṣe ìparun yóò ya ni lẹ́nu, yóò máa ṣe àṣeyọrí nínú ohun gbogbo ń ṣe. Yóò run àwọn alágbára àti àwọn ènìyàn mímọ́. 25 Nípa àrékérekè rẹ̀, yóò ̀tàn gbèrú, yóò gbé ara rẹ̀ ga nínú ọkàn rẹ̀, nígbà wọ́n àlàáfíà , yóò pa àwọn ènìyàn run, nígbà wọn tẹ́lẹ̀, yóò lòdì olórí àwọn ọmọ-aládé, síbẹ̀, a ó pa á run ṣùgbọ́n í ṣe nípa agbára ènìyàn.

26 "Ìran alẹ́ àti ti òwúrọ̀, a fihàn ́ jẹ́ òtítọ́, ṣùgbọ́n pa ìran náà mọ́, nítorí , ó jẹ mọ́ ti ọjọ́ iwájú."

27 Èmi Daniẹli ṣe àárẹ̀ fún ọjọ́ mélòó kan. Nígbà náà, mo dìde, mo ń iṣẹ́ ọba lọ. Ìran náà lẹ́, mi.

Veja também