Publicidade

Daniel 9

Àdúrà Daniẹli

1 ọdún kìn-ín-ní Dariusi ọmọ Ahaswerusi, ẹni a Media, òun jẹ ọba lórí ìjọba Babeli. 2 ọdún kìn-ín-ní ìjọba rẹ̀, èmi Daniẹli fi iyè i láti inú ìwé, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa wòlíì Jeremiah, , àádọ́rin ọdún ni Jerusalẹmu yóò fi ahoro. 3 Nígbà náà, ni mo yípadà Olúwa Ọlọ́run, mo bẹ̀ ́ pẹ̀àdúrà àti ̀bẹ̀, pẹ̀àwẹ̀, aṣọ ̀fọ̀ àti eérú.

4 Mo gbàdúrà Olúwa Ọlọ́run mi, mo jẹ́wọ́ :

"Ìwọ Olúwa, Ọlọ́run ó tóbi, ó ̀, ẹni ń pa májẹ̀ìfẹ́ mọ́, pẹ̀àwọn ó ìfẹ́ rẹ̀ àti àwọn ó ń pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́. 5 Àwa ti ṣẹ̀, a ti ṣe búburú. Àwa ti hu ìwà búburú, a ti ṣe ̀tẹ̀, a ti padà kúrò nínú àwọn àṣẹ àti àwọn ìlànà rẹ̀. 6 Àwa fetí àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ, ẹni ó sọ̀rọ̀ orúkọ rẹ àwọn ọba wa, àwọn ọmọ-aládé àti àwọn baba wa, àti gbogbo ènìyàn ilẹ̀ náà.

7 "Olúwa ìwọ ni olódodo, ṣùgbọ́n báyìí ìtìjú àwọn ènìyàn Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu àti gbogbo Israẹli gbogbo orílẹ̀-èdè ìwọ ti fọ́n wa nítorí àìṣòótọ́ wa . 8 Háà! Olúwa, àwa àti àwọn ọba wa, àwọn ọmọ-aládé, àti àwọn baba wa, ìtìjú wa nítorí àwa ti dẹ́ṣẹ̀ . 9 Olúwa Ọlọ́run wa àánú, ó ń dáríjì, àwa tilẹ̀ ti ṣe ̀tẹ̀ i; 10 àwa gbọ́rọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa, a pa àwọn òfin rẹ mọ́, èyí ó fún wa nípasẹ̀ àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ̀. 11 Gbogbo Israẹli ti ṣẹ̀ òfin rẹ, wọ́n ti yípadà kúrò ̀dọ̀ rẹ, wọ́n kọ̀ láti ṣe ìgbọ́ràn .

"Nígbà náà ni ègún àti ìdájọ́ a kọ sílẹ̀ pẹ̀ìbúra nínú òfin Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run sórí i wa, nítorí àwa ti sẹ̀ . 12 Ìwọ ti ̀rọ̀ o sọ wa sẹ àti lórí àwọn alákòóso wa, nípa mímú ibi ńlá wa, irú èyí ì ṣẹlẹ̀ lábẹ́ ̀run, ó ti ṣẹlẹ̀ Jerusalẹmu yìí. 13 a ti kọ ́ sínú òfin Mose bẹ́̀ ni gbogbo ibi yìí ti wa, síbẹ̀ a bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere Olúwa Ọlọ́run wa, nípa yíyí padà a kúrò nínú ̀ṣẹ̀ wa a mọ òtítọ́ rẹ. 14 Olúwa jáfara láti ibi náà sórí wa, nítorí olódodo ni Olúwa Ọlọ́run wa nínú u gbogbo ohun ó ń ṣe; síbẹ̀ àwa ṣe ìgbọ́ràn i.

15 "ìsinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run wa, ẹni ó àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti , pẹ̀ọwọ́ agbára, ó fún ara rẹ̀ orúkọ ó títí di òní, a ti ṣẹ̀, a ti ṣe búburú. 16 Olúwa, ìbámu pẹ̀ìwà òdodo rẹ, ìbínú àti ìrunú rẹ padà kúrò Jerusalẹmu ìlú u rẹ, òkè mímọ́ rẹ. ̀ṣẹ̀ wa àti àìṣedéédéé àwọn baba wa ti Jerusalẹmu àti ènìyàn rẹ di ̀gàn fún gbogbo àwọn ó wọn .

17 "Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, gbọ́ àdúrà àti ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ, nítorí i tìrẹ Olúwa, fi ojú àánú wo ibi mímọ́ rẹ ó ti dahoro. 18 Tẹ́ etí rẹ sílẹ̀, Ọlọ́run, o gbọ́; ya ojú rẹ sílẹ̀, o wo ìdahoro ìlú a ń fi orúkọ rẹ . Àwa gbé ̀bẹ̀ wa kalẹ̀ níwájú u rẹ nítorí a jẹ́ olódodo, ṣe nítorí àánú ńlá rẹ. 19 Olúwa, fetísílẹ̀! Olúwa, dáríjì! Olúwa, gbọ́ o ṣe é! Nítorí i tìrẹ, Ọlọ́run mi, ṣe pẹ́ títí, nítorí ìlú rẹ àti àwọn ènìyàn rẹ ń jẹ́ orúkọ mọ́ lára."

Àádọ́rin ̀sẹ̀

20 mo ṣe ń sọ̀rọ̀, mo ń gba àdúrà, mo ń jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ mi àti ̀ṣẹ̀ àwọn Israẹli ènìyàn mi, mo ń ̀bẹ̀ mi tọ Olúwa Ọlọ́run mi nítorí òkè mímọ́ rẹ. 21 mo ṣe ń gba àdúrà náà lọ́wọ́, Gabrieli ọkùnrin mo nínú ìran ìṣáájú, yára kánkán ̀dọ̀ mi àkókò ẹbọ àṣálẹ́. 22 Ó jẹ́ ó mi, ó fún mi , "Daniẹli, mo láti jẹ́ o mọ̀ o òye. 23 o ṣe bẹ̀rẹ̀ nígbà àdúrà, a fún ìdáhùn kan, èyí mo láti sọ fún , nítorí ìwọ jẹ́ àyànfẹ́ gidigidi. Nítorí náà, gba ̀rọ̀ náà yẹ̀ ìran náà :

24 "Àádọ́rin ̀sẹ̀ ni a pàṣẹ fún àwọn ènìyàn rẹ àti fún àwọn ìlú mímọ́ rẹ láti parí ìrékọjá, láti fi òpin ̀ṣẹ̀, láti ṣe ètùtù ìwà búburú, láti òdodo títí ayé , láti ṣe èdìdì ìran àti wòlíì àti láti fi òróró yan Ibi Mímọ́ Jùlọ.

25 "Nítorí náà, mọ èyí , láti ìgbà a ti gbé ̀rọ̀ náà jáde a tún Jerusalẹmu ṣe, a tún kọ́, títí ìgbà ọmọ-aládé, ẹni òróró náà, alákòóso wa yóò fi , ó jẹ́ ̀sẹ̀ méje àti ̀sẹ̀ méjìlélọ́gọ́ta, a ó tún ìgboro àti yàrá rẹ̀ mọ, ṣùgbọ́n àkókò wàhálà ni. 26 Lẹ́yìn ̀sẹ̀ méjìlélọ́gọ́ta, a ó Ẹni òróró náà kúrò, ohun kan. Àwọn ènìyàn ọmọ-aládé náà yóò ni yóò pa ìlú náà àti ibi mímọ́ run. Òpin yóò ìkún omi, ogun yóò máa títí òpin, a ti pàṣẹ ìdahoro. 27 9.27: Da 11.31; 12.11; Mt 24.15; Mk 13.14.Yóò fi ìdí i májẹ̀kan múlẹ̀ pẹ̀̀pọ̀lọpọ̀ fún ̀sẹ̀ kan. àárín ̀sẹ̀ ni yóò òpin ẹbọ àti ọrẹ ẹbọ. Àti lórí apá kan ni yóò ìríra ó ìdahoro , títí òpin a ti pàṣẹ lórí asọnidahoro yóò fi padà fi a."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-