Publicidade

Eclesiastes 10

1 Gẹ́gẹ́ òkú eṣinṣin ń fún òróró ìkunra òórùn búburú,

bẹ́̀ náà ni òmùgọ̀ díẹ̀ ṣe ń bo ọgbọ́n àti ọlá mọ́lẹ̀.

2 Ọkàn ọlọ́gbọ́n a máa ṣí ohun ó tọ̀,

ṣùgbọ́n ọkàn òmùgọ̀ ohun dára.

3 Kódà ó ti ṣe ń rìn láàrín ̀,

òmùgọ̀ ọgbọ́n

a máa fihan gbogbo ènìyàn ó ti gọ̀ .

4 ìbínú alákòóso dìde lòdì ,

ma ṣe fi ààyè rẹ sílẹ̀;

ìdákẹ́ jẹ́́jẹ́ le è àṣìṣe ńlá.

5 Ohun ibi kan mo ti lábẹ́ oòrùn,

irú àṣìṣe ó dìde láti ̀dọ̀ alákòóso.

6 A gbé aṣiwèrè ̀pọ̀ ipò ó ga jùlọ,

nígbà ọlọ́rọ̀ gba àwọn ààyè ó kéré jùlọ.

7 Mo ti ẹrú lórí ẹṣin,

nígbà ọmọ-aládé ń fi ẹsẹ̀ rìn ẹrú.

8 Ẹnikẹ́ni ó gbẹ́ kòtò, ó le è ṣubú sínú rẹ̀;

ẹnikẹ́ni ó la inú ògiri, ejò le è ṣán an.

9 Ẹnikẹ́ni ó gbe òkúta le è ìpalára láti ipasẹ̀ wọn;

ẹnikẹ́ni ó la ìtì igi le è ìpalára láti ipasẹ̀ wọn.

10 àáké

̀gbẹ́ rẹ̀ pípọ́n;

yóò nílò agbára púpọ̀

ṣùgbọ́n ọgbọ́n orí ni yóò àṣeyọrí .

11 ejò ṣán ni a lo oògùn rẹ̀,

èrè kankan fún olóògùn rẹ̀.

12 ̀rọ̀ ó láti ẹnu ọlọ́gbọ́n a máa oore-ọ̀fẹ́

ṣùgbọ́n ètè òmùgọ̀ fúnra rẹ̀ ni yóò parun.

13 Ìbẹ̀rẹ̀ ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ́ òmùgọ̀;

ìparí rẹ̀ jẹ́ ìsínwín búburú.

14 Wèrè a máa ṣàfikún ̀rọ̀.

ẹni ó mọ ohun ó ń bọ̀

ta ni ó le è sọ fún un ohun yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀?

15 Iṣẹ́ aṣiwèrè a máa a lágara

mọ ojú ̀ìlú.

16 Ègbé ni fún , ìwọ ilẹ̀ ọba ń ṣe ìránṣẹ́ rẹ̀

àti àwọn ọmọ-aládé ń ṣe àsè òwúrọ̀.

17 Ìbùkún ni fún , ìwọ ilẹ̀ èyí ọba rẹ̀ jẹ́ ọmọ ọlọ́,

àti àwọn ọmọ-aládé ń jẹun àsìkò ó yẹ,

fún ìlera, í ṣe fún ìmutípara.

18 ènìyàn ń lọ́ra, àjà ilé a máa

ọwọ́ rẹ̀ ń ṣe ̀lẹ, ilé a máa .

19 ̀rín rínrín ni a ṣe àsè fún,

wáìnì a máa ayé dùn,

ṣùgbọ́n owó ni ìdáhùn ohun gbogbo.

20 Ma ṣe ọba, kódà nínú èrò rẹ,

tàbí o ṣépè fún ọlọ́rọ̀ ibi ibùsùn rẹ,

nítorí ẹyẹ ojú ̀run le è gbé ̀rọ̀ rẹ

ẹyẹ ó ìyẹ́ apá le è fi ẹjọ́ ohun o sọ sùn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-