Publicidade

Eclesiastes 7

Ọgbọ́n

1 Orúkọ rere sàn ju ìpara olóòórùn dídùn lọ,

ọjọ́ ikú dára ju ọjọ́ a ènìyàn lọ.

2 Ó dára láti lọ ilé ̀fọ̀

ju ibi àsè,

nítorí ikú jẹ́ àyànmọ́ gbogbo ènìyàn;

alààyè èyí ọkàn.

3 Ìbànújẹ́ dára ju ̀rín lọ,

ó le è ojú rẹ̀ dàrú,

ṣùgbọ́n yóò jẹ́ àyà rẹ le.

4 Ọkàn ọlọ́gbọ́n ilé ̀fọ̀,

ṣùgbọ́n ọkàn òmùgọ̀ ilé àríyá.

5 Ó dára láti gba ìbáwí ọlọ́gbọ́n,

ju fífetísílẹ̀ orin òmùgọ̀ lọ.

6 Gẹ́gẹ́ ̀gún ti ń dún lábẹ́ ìkòkò

ni ̀rín òmùgọ̀.

Asán ni eléyìí pẹ̀.

7 Ìrẹ́jẹ a máa sọ ọlọ́gbọ́n di òmùgọ̀,

àbẹ̀tẹ́lẹ̀ máa ń ba ìwà jẹ́ ni.

8 Òpin ̀rọ̀ dára ju ìbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ lọ,

sùúrù dára ju ìgbéraga lọ.

9 ṣe yára bínú ọkàn rẹ

nítorí orí ẹsẹ̀ òmùgọ̀ ni ìbínú ń gbé.

10 ṣe sọ , "ni ìdí àtijọ́ fi dára ju èyí?"

Nítorí , ọgbọ́n láti béèrè irú ìbéèrè bẹ́̀.

11 Ọgbọ́n, gẹ́gẹ́ ogún ìní jẹ́ ohun ó dára

ó ṣe àwọn ó oòrùn láǹfààní.

12 Ọgbọ́n jẹ́ ààbò

gẹ́gẹ́ owó ti jẹ́ ààbò

ṣùgbọ́n àǹfààní òye ni èyí

ọgbọ́n a máa tọ́̀ẹni ó .

13 Wo ohun Ọlọ́run ti ṣe:

"Ta ni ó le è to

ohun ó ti ṣe wíwọ́?"

14 Nígbà àkókò dára, jẹ́ inú rẹ dùn,

ṣùgbọ́n nígbà àkókò dára, ó:

Ọlọ́run ó èkínní

náà ni ó èkejì.

Nítorí náà, ènìyàn le è ṣàwárí

ohun kankan nípa ọjọ́ iwájú rẹ̀.

15 Nínú ayé àìní ìtumọ̀ yìí ni mo ti gbogbo èyí

ènìyàn olóòtítọ́, ọkùnrin olódodo ń parun nínú òtítọ́ rẹ̀

ìkà ènìyàn ń gbé ìgbé ayé pípẹ́ nínú ìkà rẹ̀.

16 ṣe jẹ́ olódodo jùlọ

tàbí ọlọ́gbọ́n jùlọ

o fi fẹ́ pa ara rẹ run?

17 Ìwọ ma ṣe búburú jùlọ ìwọ ṣe aṣiwèrè,

èéṣe ìwọ yóò fi ọjọ́ rẹ

18 Ó dára láti ̀kan

o ṣe fi èkejì sílẹ̀.

Ọkùnrin ó bẹ̀Ọlọ́run yóò bọ́ lọ́wọ́ gbogbo àrékérekè.

19 Ọgbọ́n máa ń ọlọ́gbọ́n ènìyàn agbára

ju alákòóso mẹ́wàá lọ ìlú.

20 olódodo ènìyàn kan láyé

ó ṣe ohun ó tọ́ dẹ́ṣẹ̀ rárá.

21 ṣe kíyèsi gbogbo ̀rọ̀ ènìyàn ń sọ

bẹ́̀ kọ́, o le è gbọ́ ìránṣẹ́ rẹ ń ṣépè fún .

22 o mọ̀ nínú ọkàn rẹ

̀pọ̀ ìgbà ni ìwọ fúnra rẹ̀ ti ṣépè fún àwọn ẹlòmíràn.

23 Gbogbo èyí ni mo ti dánwò nípa ọgbọ́n, mo ,

"Mo pinnu láti jẹ́ ọlọ́gbọ́n";

ṣùgbọ́n eléyìí ti lọ.

24 Ohun ó ọgbọ́n le è jẹ́,

ó ti lọ jìnnà, ó jinlẹ̀

ta ni ó le è ṣe àwárí rẹ̀?

25 Mo ó nínú ọkàn mi láti mọ̀,

láti àti láti ṣàwárí ọgbọ́n

àti ìdí ohun gbogbo, àti láti mọ ìwà àgọ́

búburú àti ti ìsínwín tàbí òmùgọ̀.

26 Mo ohun ó korò ju ikú lọ

obìnrin ó jẹ́ ̀bìtì,

ọkàn rẹ̀ jẹ́ tàkúté

ọwọ́ rẹ̀ jẹ́ ̀wọ̀n,

ọkùnrin ó tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn yóò le è yọ sílẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni dẹ́ṣẹ̀ le è bọ́ nínú tàkúté rẹ̀.

27 Oniwaasu , "ó, eléyìí ni ohun mo ti ṣàwárí:

"Mímú ohun kan pọ̀ mọ́ òmíràn láti ṣàwárí ìdí ohun gbogbo.

28 Nígbà mo ń a kiri

ṣùgbọ́n n i

mo ọkùnrin ó dúró dáradára kan láàrín ẹgbẹ̀rún (1,000),

ṣùgbọ́n n obìnrin,

kankan ó dúró láàrín gbogbo wọn.

29 Eléyìí nìkan ni mo ì :

Ọlọ́run ìran ènìyàn dáradára,

ṣùgbọ́n ènìyàn ti lọ láti ṣàwárí ohun púpọ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-