Pular para o conteúdo
Publicidade

Efésios 5

22 5.22–6.9: Kl 3.18–4.1. ̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ fún Olúwa. 23 Nítorí ọkọ ni ó ń ṣe orí aya, gẹ́gẹ́ Kristi i ṣe orí ìjọ, òun si ń ṣe ara rẹ̀, Òun ni Olùgbàlà rẹ̀. 24 Nítorí náà gẹ́gẹ́ ìjọ i tẹríba fún Kristi, bẹ́̀ àwọn aya máa ṣe ọkọ wọn ohun gbogbo.

25 ̀yin ọkọ, fẹ́ràn àwọn aya yín, gẹ́gẹ́ Kristi fẹ́ràn ìjọ, ó fi ara rẹ̀ fún un. 26 òun sọ ́ di mímọ́ lẹ́yìn ó fi ̀rọ̀ wẹ̀ ́ nínú agbada omí. 27 òun un sọ́dọ̀ ara rẹ̀ ìjọ ó ògo àìlábàwọ́n, tàbí àlébù kan, tàbí irú nǹkan bá-wọ̀n-ọn-nì: ṣùgbọ́n ó jẹ́ mímọ́ àti aláìlábùkù. 28 Bẹ́̀ ó tọ́ àwọn ọkùnrin máa fẹ́ràn aya wọn gẹ́gẹ́ ara àwọn fúnra wọn. 29 Nítorí ẹnìkan ó ti kórìíra ara rẹ̀; ṣe ó máa bọ́ ó máa ṣìkẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ Kristi ti ń ṣe ìjọ. 30 Nítorí àwa ni ̀ara rẹ̀, àti ẹran-ara rẹ̀, àti egungun ara rẹ̀. 31 5.31: Gẹ 2.24.Nítorí èyí ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, òun yóò dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, àwọn méjèèjì yóò di ara kan. 32 Àṣírí ńlá èyí: ṣùgbọ́n èmí ń sọ nípá ti Kristi àti ìjọ. 33 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yín fẹ́ràn aya rẹ̀, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ òun fúnra rẹ̀; aya ó bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀.

Veja também