Publicidade

Filipenses 2

Kọ́ ìwà ìrẹ̀lẹ̀ Kristi

1 ìwọ ìmúlọ́kànle nítorí ìwọ ìṣọ̀kan pẹ̀Kristi, bi ìtùnú kan nínú ìfẹ́ rẹ̀, ìdàpọ̀ ̀kan , ìyọ́àti ìṣeun , 2 síbẹ̀ ayọ̀ mi kún nínú ìṣọ̀kan yín, nípa ìfẹ́ kan náà, wíwà ̀kan náà àti ète kan náà. 3 ṣe ohunkóhun nínú ìlépa ara tàbí ògo asán, ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ọkàn olúkúlùkù ro àwọn ẹlòmíràn ẹni ti ó sàn ju òun lọ. 4 olúkúlùkù yín ṣe ro ohun ti ara rẹ̀ nìkan, ṣùgbọ́n ti ẹlòmíràn pẹ̀.

5 Nínú ìbáṣepọ̀ yin pẹ̀àwọn ẹlòmíràn, ni irú ìlépa ọkàn náà ti Kristi Jesu.

6 Ẹni , o tilẹ̀ jẹ́ ìrísí Ọlọ́run,

á ohun ìbá fi ìwọra gbámú láti Ọlọ́run dọ́gba.

7 Ṣùgbọ́n ó bọ́ ògo rẹ̀ sílẹ̀,

ó àwọ̀ ìránṣẹ́,

a ṣe é ni àwòrán ènìyàn.

8 Ó àwòrán ènìyàn,

ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀,

o tẹríba títí de ojú ikú,

àní ikú lórí àgbélébùú.

9 Nítorí náà, Ọlọ́run ti gbé e ga ipele ó ga jùlọ,

ó ti fi orúkọ kan ti ó borí gbogbo orúkọ fún un,

10 ni orúkọ Jesu ni gbogbo eékún máa wólẹ̀,

̀run, àti orí ilẹ̀ ayé àti ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,

11 àti gbogbo ahọ́n jẹ́wọ́ , Jesu Kristi ni Olúwa,

fún ògo Ọlọ́run Baba.

Títàn gẹ́gẹ́ àwọn ìràwọ̀

12 Nítorí náà ̀yin ará mi, gẹ́gẹ́ ̀yin ti ń gbọ́rọ̀ nígbà gbogbo, í ṣe nígbà ti mo lọ́dọ̀ yín nìkan, ṣùgbọ́n pàápàá nísinsin yìí èmi ni àárín yín, máa ṣiṣẹ́ ìgbàlà yín yọrí pẹ̀ìbẹ̀àti ìwárìrì, 13 nítorí Ọlọ́run ni ó n ṣiṣẹ́ nínú yín, láti fẹ́ àti láti ṣiṣẹ́ fún ète rere rẹ̀.

14 máa ṣe ohun gbogbo láìsí ìkùnsínú àti ìjiyàn. 15 ̀yin jẹ́ aláìlẹ́gàn àti oníwà mímọ́, ọmọ Ọlọ́run, aláìlábàwọ́n, láàrín oníwà wíwọ́ àti alárékérekè orílẹ̀-èdè láàrín àwọn ẹni a ń yín ìmọ́lẹ̀ ayé. 16 ṣe di ̀rọ̀ ìyè gírígírí, èmi ṣògo ni ọjọ́ Kristi èmi sáré lásán, bẹ́̀ ni èmi ṣe làálàá lásán. 17 Ṣùgbọ́n, a tilẹ̀ ń ọtí-ìrúbọ sórí ẹbọ iṣẹ́ ìsìn ìgbàgbọ́ yín, inú mi dùn, mo ń gbogbo yín yọ̀ pẹ̀. 18 Bákan náà ni ̀yin máa yọ̀, máa mi yọ̀ pẹ̀.

Timotiu àti Epafiroditu

19 Mo ni ìrètí nínú Jesu Olúwa, láti rán Timotiu yín ni àìpẹ́ yìí, èmi pẹ̀ni ìfọ̀kànbalẹ̀ nígbà mo gbúròó yín. 20 Nítorí èmi ni ẹlòmíràn ó dàbí rẹ̀, yóò máa fi tinútinú ṣe àníyàn yín. 21 Nítorí gbogbo wọn ni ó tọ́nǹkan ti ara wọn, í ṣe àwọn nǹkan ti Jesu Kristi. 22 Ṣùgbọ́n ̀yin mọ̀ Timotiu pegedé, gẹ́gẹ́ ọmọ lọ́dọ̀ baba rẹ̀, bẹ́̀ ni ó ti ń mi ṣiṣẹ́ pọ̀, nínú iṣẹ́ ìyìnrere. 23 Nítorí náà, mo ìrètí láti rán yín àìpẹ́ mo wòye yóò ti fún mi. 24 Ṣùgbọ́n mo gbẹ́kẹ̀nínú Olúwa, èmi tìkára mi pẹ̀yóò àìpẹ́.

25 Mo á n ṣàìrán Epafiroditu arákùnrin mi yín, àti olùbáṣiṣẹ́ pọ̀ mi, àti ọmọ-ogun ẹlẹgbẹ́ mi, ìránṣẹ́ yín pẹ̀, rán láti ṣè ránṣẹ́ fún mi nínú àìní mi. 26 Nítorí ọkàn rẹ̀ gbogbo yín, ó kún fún ìbànújẹ́, nítorí ̀yin gbọ́ ó ṣe àìsàn. 27 Nítòótọ́ ni ó ti ṣe àìsàn títí ojú ikú, ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti ṣàánú fún un; í í ṣe fún òun nìkan, ṣùgbọ́n fún èmi pẹ̀èmi ṣe ni ìbànújẹ́ lórí ìbànújẹ́. 28 Nítorí náà ni mo ṣe ìtara láti rán an, nígbà ̀yin tún i, ̀yin yọ̀ àti ìkáyà sókè mi dínkù. 29 Nítorí náà, fi ayọ̀ púpọ̀ gbà á nínú Olúwa; máa bu ọlá fún irú àwọn ẹni bẹ́̀. 30 Nítorí iṣẹ́ Kristi ni ó ṣe súnmọ́ ẹnu-ọ̀ikú, ó fi ̀ara rẹ̀ wéwu, láti mu àìtó iṣẹ́ ìsìn yín mi kún.

Veja também

Publicidade
Filipenses
Ver todos os capítulos de Filipenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-