Pular para o conteúdo
Publicidade

Filipenses 2

5 2.5-8: Mt 11.29; 20.28; Jh 1.1; 2Kọ 8.9; Hb 5.8. Nínú ìbáṣepọ̀ yin pẹ̀àwọn ẹlòmíràn, ni irú ìlépa ọkàn náà ti Kristi Jesu.

6 Ẹni , o tilẹ̀ jẹ́ ìrísí Ọlọ́run,

á ohun ìbá fi ìwọra gbámú láti Ọlọ́run dọ́gba.

7 Ṣùgbọ́n ó bọ́ ògo rẹ̀ sílẹ̀,

ó àwọ̀ ìránṣẹ́,

a ṣe é ni àwòrán ènìyàn.

8 Ó àwòrán ènìyàn,

ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀,

o tẹríba títí de ojú ikú,

àní ikú lórí àgbélébùú.

Veja também

Filipenses
Ver todos os capítulos de Filipenses