Pular para o conteúdo
Publicidade

Filipenses 2

9 2.9-11: Ro 10.9; 14.9; Ef 1.20-21. Nítorí náà, Ọlọ́run ti gbé e ga ipele ó ga jùlọ,

ó ti fi orúkọ kan ti ó borí gbogbo orúkọ fún un,

10 ni orúkọ Jesu ni gbogbo eékún máa wólẹ̀,

̀run, àti orí ilẹ̀ ayé àti ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,

11 àti gbogbo ahọ́n jẹ́wọ́ , Jesu Kristi ni Olúwa,

fún ògo Ọlọ́run Baba.

Veja também

Filipenses
Ver todos os capítulos de Filipenses