Publicidade

Filipenses 3

ìgbẹ́kẹ̀ẹlẹ́ran ara

1 àkótán ará, máa yọ̀ nínú Olúwa wa. í ṣe ìnira fún mi láti kọ̀ohun kan náà yín, ṣùgbọ́n fún yín ó jẹ́ ohun ààbò. 2 kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn ajá, kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn oníṣẹ́ búburú, kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn onílà. 3 Nítorí àwa ni onílà, ń sin Ọlọ́run nípa ti ̀, àwa ń ṣògo nínú Kristi Jesu, àwa ìgbẹ́kẹ̀nínú ẹran-ara. 4 èmi tìkára mi pẹ̀ti ìgbẹ́kẹ̀nínú ara.

ẹnikẹ́ni òun ni ìgbẹ́kẹ̀nínú ara, tèmi tilẹ̀ pọ̀, 5 ẹni a kọ nílà ọjọ́ kẹjọ, láti inú kùkùté Israẹli , láti inú ̀Benjamini, Heberu láti inú Heberu ; nítorí, ti òfin Farisi ni èmi; 6 ti ìtara, èmi ń ṣe inúnibíni ìjọ; ti òdodo ó nínú òfin, mo jẹ́ aláìlẹ́gàn.

7 Ṣùgbọ́n ohunkóhun ó ti jásí èrè fún mi, àwọn ni mo ti òfo nítorí Kristi. 8 Nítòótọ́ láìṣe àní àní mo ka ohun gbogbo òfo nítorí ìtayọ ìmọ̀ Kristi Jesu Olúwa mi; nítorí ẹni ti mo ti ṣòfò ohun gbogbo, mo si wọn ohun èrè, èmi jèrè Kristi, 9 a mi nínú rẹ̀, láìní òdodo èmi tìkára mi, ó ti inú òfin , ṣùgbọ́n èyí ó ti inú ìgbàgbọ́ nínú Kristi, òdodo láti ̀dọ̀ Ọlọ́run nípasẹ̀ ìgbàgbọ́. 10 Èmi mọ̀ ́n, àti agbára àjíǹde rẹ̀, àti láti jẹ́ alábápín nínú ìyà rẹ̀ nígbà mo fi ara mọ́ ọn nínú ikú rẹ̀; 11 nípasẹ̀ bẹ́̀ èmi àjíǹde kúrò nínú òkú.

12 í ṣe ọwọ́ mi ti tẹ̀ ́ , tàbí mo ti di pípé, ṣùgbọ́n èmi ń lépa i, ọwọ́ mi yóò tẹ èrè náà nítorí èyí a ti mímú pẹ̀, láti ̀dọ̀ Kristi Jesu . 13 Ará, èmi kara mi ẹni ti ọwọ́ rẹ̀ ti tẹ̀ ́ , ṣùgbọ́n ohun kan yìí ni èmi ń ṣe, èmi ń gbàgbé àwọn nǹkan ó ti kọjá. Lẹ́yìn náà mo ń nàgà wo àwọn nǹkan ó níwájú. 14 Èmi ń lépa láti òpin eré ìje náà fún èrè ìpè gíga Ọlọ́run nínú Kristi Jesu.

15 Nítorí náà, jẹ́ àwa a dàgbà nípa ti ̀ni èrò yìí; ̀yin èrò mìíràn nínú ohunkóhun, èyí náà pẹ̀ni Ọlọ́run yóò fihàn yín. 16 Kìkì , ki a ma gbe ìgbé ayé gẹ́gẹ́ bi èyí ti a ri gba.

17 Ará, jùmọ̀ ṣe àfarawé mi, ṣe àkíyèsí àwọn ń rìn bẹ́̀, àní ti wa fún àpẹẹrẹ. 18 Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ń rìn, nípasẹ̀ àwọn ẹni mo ti ń fún yín nígbàkígbà, àní, mo ń sọkún mo ti ń fún yín nísinsin yìí, , ̀àgbélébùú Kristi ni wọ́n. 19 Ìgbẹ̀yìn wọn ni ìparun, ikùn wọn ni Ọlọ́run wọn, wọ́n ń ṣògo nínú ìtìjú wọn, àwọn ẹni ń tọ́ohun ti ayé. 20 Nítorí ìlú ìbílẹ̀ ń bẹ̀ ̀run, láti ibi ti àwa pẹ̀gbé ń fojúsọ́fún Olùgbàlà, Jesu Kristi Olúwa. 21 Ẹni yóò sọ ara ìrẹ̀lẹ̀ wa di ̀tún ó ara ògo rẹ̀ mu, nípa agbára ó ó ṣe é ṣe fún un láti tẹ orí ohun gbogbo fún ara rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Filipenses
Ver todos os capítulos de Filipenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-