Publicidade

Filipenses 4

1 Nítorí náà ̀yin ará mi olùfẹ́, ti mo ń ṣàfẹ́gidigidi, ayọ̀ àti adé mi, dúró ṣinṣin bẹ́̀ nínú Olúwa, ̀yin olùfẹ́ mi.

Àwọn ̀rọ̀ ìyànjú

2 Èmi ń bẹ̀ Euodia, mo ń bẹ Sintike, wọn inú kan náà nínú Olúwa. 3 Mo bẹ̀ yin pẹ̀alájọru àjàgà mi tòótọ́, ran àwọn obìnrin wọ̀nyí lọ́wọ́, nítorí wọn mi ṣiṣẹ́ pọ̀ ìfẹ̀gbẹ́-kẹ̀gbẹ́ nínú ìyìnrere, àti Klementi pẹ̀, àti àwọn olùbáṣiṣẹ́ mi yòókù pẹ̀, orúkọ àwọn ń bẹ nínú ìwé ìyè.

4 máa yọ̀ nínú Olúwa nígbà gbogbo: mo tún . máa yọ̀. 5 jẹ́ ki ìpamọ́ra yín di mímọ́ fún gbogbo ènìyàn, Olúwa ń bẹ nítòsí. 6 ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ̀bẹ̀ pẹ̀ìdúpẹ́, máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run. 7 Àti àlàáfíà Ọlọ́run, ó ju ìmòye gbogbo lọ, yóò pa ọkàn àti èrò yín mọ nínú Kristi Jesu.

8 àkótán, ará, ohunkóhun í ṣe òtítọ́, ohunkóhun í ṣe ̀wọ̀, ohunkóhun í ṣe títọ́ ohunkóhun í ṣe mímọ́, ohunkóhun í ṣe fífẹ́, ohunkóhun ó ni ìròyìn rere, ìwà títọ́ kan , ìyìn kan , máa gba nǹkan wọ̀nyí . 9 Àwọn nǹkan ̀yin ti kọ́, ̀yin ti gbà, ̀yin ti gbọ́, ̀yin ti lọ́wọ́ mi, máa ṣe wọ́n: Ọlọ́run àlàáfíà yóò pẹ̀yín.

Àwọn ọpẹ́ fún àwọn ̀bùn wọn

10 Èmi yọ̀ gidigidi nínú Olúwa , nísinsin yìí, ̀yin tún ti sọjí nínú àníyàn ọkàn yín mi, nítòótọ́ ọkàn yín ń fàmọ́ mi ṣùgbọ́n àǹfààní . 11 í ṣe èmi ń sọ nítorí àìní: nítorí ni ipòkípò mo , mo kọ́ láti ìtẹ́lọ́rùn nínú rẹ̀. 12 Mo mọ̀ ohun o jẹ láti wa nínú àìní, mo mọ ohun ó jẹ láti ni lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Nínú ohunkóhun àti nínú ohun gbogbo mo ti kọ́ àṣírí láti máa jẹ́ àjẹyó tàbí láti ni àìjẹun, láti máa ni ànító àti láti ṣe aláìní. 13 Èmi le ṣe ohun gbogbo nínú Kristi ẹni ti ń fi agbára fún mi.

14 Ṣùgbọ́n ̀yin ṣeun gidigidi ti ̀yin ṣe alábápín nínú ìpọ́njú mi. 15 ̀yin pàápàá mọ̀ pẹ̀, ̀yin ará Filipi, ni ìbẹ̀rẹ̀ ìyìnrere, nígbà mo kúrò ni Makedonia, ìjọ kan ti ó mi ń ṣe alábápín ti gbígbà àti fífún ni, ṣe ̀yin nìkan ṣoṣo. 16 Nítorí Tẹsalonika ̀yin fi nǹkan ránṣẹ́, lẹ́̀kan fún àìní mi. 17 í ṣe nítorí ti èmi ń fẹ́ ̀bùn náà, ṣùgbọ́n èmi ń fẹ́ èso ti yóò máa di púpọ̀ nítorí yín. 18 Ṣùgbọ́n mo ohun gbogbo, mo ti di púpọ̀, mo tún ni lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nígbà ti mo gba nǹkan wọ̀nyí lọ́wọ́ Epafiroditu a ti rán láti lọ́dọ̀ yín, ọrẹ olóòórùn dídùn, ẹbọ ìtẹ́wọ́gbà, í ṣe inú dídùn gidigidi Ọlọ́run. 19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run mi yóò pèsè kíkún fún gbogbo àìní yín, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ rẹ̀ nínú ògo nínú Kristi Jesu.

20 Ṣùgbọ́n ògo ni fún Ọlọ́run àti Baba wa láé àti láéláé. Àmín.

̀rọ̀ ìkíni ìkẹyìn

21 olúkúlùkù ènìyàn mímọ́ nínú Kristi Jesu.

Àwọn ará ó pẹ̀mi yín.

22 Gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ yín, pàápàá àwọn ń ṣe ti agbo ilé Kesari.

23 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa, ó pẹ̀̀yín. Àmín.

Veja também

Publicidade
Filipenses
Ver todos os capítulos de Filipenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-