Pular para o conteúdo
Publicidade

Gálatas 1

1 Paulu, aposteli a rán í ṣe láti ̀dọ̀ ènìyàn , tàbí nípa ènìyàn, ṣùgbọ́n nípa Jesu Kristi àti Ọlọ́run Baba, ẹni ó i dìde kúrò nínú òkú. 2 Àti gbogbo àwọn arákùnrin ó pẹ̀mi,

àwọn ìjọ Galatia:

3 1.3: Ro 1.7. Oore-ọ̀fẹ́ yín àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa, 4 1.4: Ga 2.20; 1Tm 2.6.ẹni ó fi òun tìkára rẹ̀ dípò ̀ṣẹ̀ wa, ó gbà kúrò nínú ayé búburú ìsinsin yìí, gẹ́gẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run àti Baba wa, 5 1.5: Ro 16.27.ẹni ògo fún láé àti láéláé. Àmín.

ìyìnrere mìíràn

6 Ó mi lẹ́nu tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni ó yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, ìyìnrere mìíràn. 7 Nítòótọ́, ìyìnrere mìíràn ó tilẹ̀ ṣe àwọn kan , ń yọ yín lẹ́nu, wọ́n ń fẹ́ ìyìnrere Kristi padà. 8 1.8: 2Kọ 11.4.Ṣùgbọ́n ó ṣe àwa ni tàbí angẹli kan láti ̀run , ni ó wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí a wàásù rẹ̀ fún yín lọ, jẹ́ ó di ẹni ìfibú títí láéláé! 9 àwa ti ṣáájú, bẹ́̀ ni mo tún nísinsin yìí , ẹnìkan wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí ̀yin gbà lọ, jẹ́ ó di ẹni ìfibú títí láéláé!

10 1.10: 1Tẹ 2.4. Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ènìyàn ni èmi ń ojúrere rẹ̀ tàbí Ọlọ́run? Tàbí ènìyàn ni èmi ń fẹ́ láti ? èmi ń fẹ́ láti wu ènìyàn, èmi jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi.

Paulu ẹni Ọlọ́run

11 1.11: Ro 1.16-17. Mo fẹ́ mọ̀, ará, ìyìnrere mo wàásù í ṣe láti ipa ènìyàn. 12 N gbà á lọ́wọ́ ènìyàn kankan, bẹ́̀ ni a fi kọ́ mi, ṣùgbọ́n mo gbà á nípa ìfihàn láti ̀dọ̀ Jesu Kristi.

13 1.13: Ap 8.3. Nítorí ̀yin ti gbúròó ìgbé ayé mi nígbà àtijọ́ nínú ìsìn àwọn Júù, mo ṣe inúnibíni ìjọ ènìyàn Ọlọ́run rékọjá ààlà, mo lépa láti á jẹ́. 14 1.14: Ap 22.3.Mo ta ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi yọ nínú ìsìn àwọn Júù láàrín àwọn ìran mi, mo ni ìtara lọ́pọ̀lọ́pọ̀ òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn baba mi. 15 1.15: Ap 9.1-19; Isa 49.1; Jr 1.5.Ṣùgbọ́n nígbà ó Ọlọ́run ẹni ó sọ́tọ̀ láti inú ìyá mi , ó mi nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀. 16 Láti fi ọmọ rẹ̀ hàn nínú mi, èmi máa wàásù ìyìnrere rẹ̀ láàrín àwọn aláìkọlà; èmi ìmọ̀ lọ sọ́dọ̀ ẹnikẹ́ni, 17 bẹ́̀ ni èmi gòkè lọ Jerusalẹmu tọ àwọn í ṣe aposteli ṣáájú mi, ṣùgbọ́n mo lọ Arabia, mo tún padà Damasku.

18 1.18: Ap 9.26-30; 11.30. Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta, nígbà náà ni mo gòkè lọ Jerusalẹmu láti lọ Peteru, mo gbé ̀dọ̀ rẹ̀ ìjọ mẹ́̀́dógún, 19 èmi ri ẹlòmíràn nínú àwọn ó jẹ́ aposteli, ṣe Jakọbu arákùnrin Olúwa. 20 Nǹkan èmi ń kọ̀yín yìí, kíyèsi i, níwájú Ọlọ́run èmi ṣèké.

21 Lẹ́yìn náà mo agbègbè Siria àti ti Kilikia. 22 Mo jẹ́ ẹni a mọ̀ lójú fún àwọn ìjọ ó nínú Kristi ni Judea. 23 Wọ́n kàn gbọ́ ìròyìn , "Ẹni ó ń ṣe inúnibíni wa , ìsinsin yìí ti ń wàásù ìgbàgbọ́ náà ó ti gbìyànjú láti bàjẹ́ nígbà kan ." 24 Wọ́n yin Ọlọ́run lógo nítorí mi.

Veja também