Publicidade

Gálatas 3

Ìgbàgbọ́ tàbí iṣẹ́ òfin

1 ̀yin aláìnírònú ará Galatia! Ta ha tàn yín jẹ, ̀yin ṣe gba òtítọ́ gbọ́? ojú ẹni a fi Jesu Kristi hàn gbangba láàrín yín ni ẹni a kàn mọ́ àgbélébùú. 2 Kìkì èyí ni mo fẹ́ béèrè lọ́wọ́ yín, nípa iṣẹ́ òfin ni ̀yin gba ̀, tàbí nípa ìgbọ́ràn pẹ̀ìgbàgbọ́? 3 Báyìí ni ̀yin ṣe jẹ òmùgọ̀ ? ̀yin ó ti bẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé ìgbàgbọ́ yín nípa ti ̀, ṣé a ti sọ yín di pípé nípa ti ara ni? 4 ̀yin ha ti jìyà ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan wọ̀nyí lásán? ó ṣe nítòótọ́ lásán ni. 5 Ṣé Ọlọ́run fún yín ̀rẹ̀, ó ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrín yín nítorí ̀yin pa òfin mọ, tàbí nítorí ìgbàgbọ́ ohun gbọ́? 6 Gẹ́gẹ́ Abrahamu "Ó gba Ọlọ́run gbọ́, a á òdodo fún un."

7 jẹ́ ó é yín nígbà náà , àwọn ti ó gbàgbọ́, àwọn náà í ṣe ọmọ Abrahamu. 8 ìwé mímọ́ tẹ́lẹ̀ , Ọlọ́run yóò aláìkọlà láre nípa ìgbàgbọ́, ó wàásù ìyìnrere ṣáájú fún Abrahamu, ó ń , "Nínú rẹ̀ ni a ó bùkún fún gbogbo orílẹ̀-èdè." 9 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn i ṣe ìgbàgbọ́ jẹ́ ẹni alábùkún fún pẹ̀Abrahamu olódodo.

10 Nítorí iye àwọn ń bẹ ni ipa iṣẹ́ òfin ń bẹ lábẹ́ ègún: nítorí a kọ ́ , "Ìfibú ni olúkúlùkù ẹni dúró nínú ohun gbogbo a kọ sínú ìwé òfin láti máa ṣe wọ́n". 11 Nítorí ó dánilójú , a ẹnikẹ́ni láre níwájú Ọlọ́run nípa iṣẹ́ òfin: nítorí , "Olódodo yóò nípa ìgbàgbọ́." 12 Òfin í í ṣe ti ìgbàgbọ́: ṣùgbọ́n, "Ẹni ó ba ṣe, yóò nípa wọn." 13 Kristi ti padà kúrò lọ́wọ́ ègún òfin, ẹni a fi ṣe ègún fún wa: nítorí a ti kọ ́ , "Ìfibú ni olúkúlùkù ẹni a fi kọ́ sórí igi." 14 Ó gbà ki ìbùkún Abrahamu ba à sórí àwọn aláìkọlà nípa Kristi Jesu; àwa ba à gba ìlérí ̀nípa ìgbàgbọ́.

Òfin àti ìlérí

15 Ará, èmi ń sọ̀rọ̀ ènìyàn, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀ènìyàn ti a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, ẹni ó sọ ́ di asán, tàbí ó fi kún un mọ́. 16 Ǹjẹ́ fún Abrahamu àti fún irú-ọmọ rẹ̀ ni a ti ṣe àwọn ìlérí náà. Ìwé Mímọ́ ṣọ , "fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀," ẹni ̀pọ̀lọpọ̀; ṣùgbọ́n ẹni ̀kan ṣoṣo, "àti fún irú-ọmọ rẹ̀," èyí í ṣe Kristi. 17 Èyí ń ni : májẹ̀Ọlọ́run ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níṣàájú, òfin ti ó lẹ́yìn ọgbọ̀nlénírinwó (430) ọdún sọ ́ di asán, ó ìlérí náà di aláìlágbára. 18 Nítorí ogún náà dúró lórí ṣíṣe gẹ́gẹ́ í òfin í ṣe ti ìlérí mọ́, ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi í fún Abrahamu nípa ìlérí.

19 Ǹjẹ́ ha ni òfin? A fi kún un nítorí ìrékọjá títí irú-ọmọ a ti ṣe ìlérí fún yóò fi ; a tipasẹ̀ àwọn angẹli ṣe ìlànà rẹ̀ láti ọwọ́ alárinà kan . 20 Ǹjẹ́ onílàjà í ṣe alárinà ti ẹnìkan, ṣùgbọ́n ̀kan ni Ọlọ́run.

21 Nítorí náà òfin ha lòdì àwọn ìlérí Ọlọ́run ? a i; nítorí ìbá ṣe a ti fi òfin kan fún ni ó lágbára láti sọ ni di ààyè nítòótọ́ òdodo ìbá ti tipasẹ̀ òfin . 22 Ṣùgbọ́n ìwé mímọ́ ti fi wa gbogbo ènìyàn ni ń bẹ lábẹ́ ìdè ̀ṣẹ̀, a fi ìlérí nípa ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi fún àwọn ó gbàgbọ́.

Ọmọ Ọlọ́run

23 Ṣùgbọ́n ìgbàgbọ́ , a ti pa mọ́ lábẹ́ òfin, a wa mọ́ de ìgbàgbọ́ a ń bọ̀ fihàn. 24 Nítorí náà òfin ti jẹ́ olùtọ́láti ènìyàn sọ́dọ̀ Kristi, a wa láre nípa ìgbàgbọ́. 25 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà ìgbàgbọ́ ti , àwa lábẹ́ olùtọ́mọ́.

26 Nítorí ọmọ Ọlọ́run ni gbogbo yín, nípa ìgbàgbọ́ nínú Kristi Jesu. 27 Nítorí iye ̀yin a ti bamitiisi sínú Kristi ti gbé Kristi wọ̀. 28 le Júù tàbí Giriki, ẹrú tàbí òmìnira, ọkùnrin tàbí obìnrin nítorí ̀kan ni nínú Kristi Jesu. 29 ̀yin jẹ́ ti Kristi, ǹjẹ́ ̀yin irú-ọmọ Abrahamu, àti àrólé gẹ́gẹ́ ìlérí.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-