Publicidade

Gálatas 3

Ìgbàgbọ́ tàbí iṣẹ́ òfin

1 ̀yin aláìnírònú ará Galatia! Ta ha tàn yín jẹ, ̀yin ṣe gba òtítọ́ gbọ́? ojú ẹni a fi Jesu Kristi hàn gbangba láàrín yín ni ẹni a kàn mọ́ àgbélébùú. 2 Kìkì èyí ni mo fẹ́ béèrè lọ́wọ́ yín, nípa iṣẹ́ òfin ni ̀yin gba ̀, tàbí nípa ìgbọ́ràn pẹ̀ìgbàgbọ́? 3 Báyìí ni ̀yin ṣe jẹ òmùgọ̀ ? ̀yin ó ti bẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé ìgbàgbọ́ yín nípa ti ̀, ṣé a ti sọ yín di pípé nípa ti ara ni? 4 ̀yin ha ti jìyà ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan wọ̀nyí lásán? ó ṣe nítòótọ́ lásán ni. 5 Ṣé Ọlọ́run fún yín ̀rẹ̀, ó ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrín yín nítorí ̀yin pa òfin mọ, tàbí nítorí ìgbàgbọ́ ohun gbọ́? 6 3.6: Gẹ 15.6; Ro 4.3.Gẹ́gẹ́ Abrahamu "Ó gba Ọlọ́run gbọ́, a á òdodo fún un."

7 jẹ́ ó é yín nígbà náà , àwọn ti ó gbàgbọ́, àwọn náà í ṣe ọmọ Abrahamu. 8 3.8: Gẹ 12.3; 18.18; Ap 3.25.ìwé mímọ́ tẹ́lẹ̀ , Ọlọ́run yóò aláìkọlà láre nípa ìgbàgbọ́, ó wàásù ìyìnrere ṣáájú fún Abrahamu, ó ń , "Nínú rẹ̀ ni a ó bùkún fún gbogbo orílẹ̀-èdè." 9 3.9: Ro 4.16.Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn i ṣe ìgbàgbọ́ jẹ́ ẹni alábùkún fún pẹ̀Abrahamu olódodo.

10 3.10: De 27.26. Nítorí iye àwọn ń bẹ ni ipa iṣẹ́ òfin ń bẹ lábẹ́ ègún: nítorí a kọ ́ , "Ìfibú ni olúkúlùkù ẹni dúró nínú ohun gbogbo a kọ sínú ìwé òfin láti máa ṣe wọ́n". 11 3.11: Hk 2.4; Ro 1.17; Hb 10.38.Nítorí ó dánilójú , a ẹnikẹ́ni láre níwájú Ọlọ́run nípa iṣẹ́ òfin: nítorí , "Olódodo yóò nípa ìgbàgbọ́." 12 3.12: Le 18.5; Ro 10.5.Òfin í í ṣe ti ìgbàgbọ́: ṣùgbọ́n, "Ẹni ó ba ṣe, yóò nípa wọn." 13 3.13: De 21.23.Kristi ti padà kúrò lọ́wọ́ ègún òfin, ẹni a fi ṣe ègún fún wa: nítorí a ti kọ ́ , "Ìfibú ni olúkúlùkù ẹni a fi kọ́ sórí igi." 14 Ó gbà ki ìbùkún Abrahamu ba à sórí àwọn aláìkọlà nípa Kristi Jesu; àwa ba à gba ìlérí ̀nípa ìgbàgbọ́.

Òfin àti ìlérí

15 Ará, èmi ń sọ̀rọ̀ ènìyàn, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀ènìyàn ti a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, ẹni ó sọ ́ di asán, tàbí ó fi kún un mọ́. 16 3.16: Gẹ 12.7.Ǹjẹ́ fún Abrahamu àti fún irú-ọmọ rẹ̀ ni a ti ṣe àwọn ìlérí náà. Ìwé Mímọ́ ṣọ , "fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀," ẹni ̀pọ̀lọpọ̀; ṣùgbọ́n ẹni ̀kan ṣoṣo, "àti fún irú-ọmọ rẹ̀," èyí í ṣe Kristi. 17 3.17: Ek 12.40.Èyí ń ni : májẹ̀Ọlọ́run ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níṣàájú, òfin ti ó lẹ́yìn ọgbọ̀nlénírinwó (430) ọdún sọ ́ di asán, ó ìlérí náà di aláìlágbára. 18 3.18: Ro 11.6.Nítorí ogún náà dúró lórí ṣíṣe gẹ́gẹ́ í òfin í ṣe ti ìlérí mọ́, ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi í fún Abrahamu nípa ìlérí.

19 3.19: Ro 5.20. Ǹjẹ́ ha ni òfin? A fi kún un nítorí ìrékọjá títí irú-ọmọ a ti ṣe ìlérí fún yóò fi ; a tipasẹ̀ àwọn angẹli ṣe ìlànà rẹ̀ láti ọwọ́ alárinà kan . 20 Ǹjẹ́ onílàjà í ṣe alárinà ti ẹnìkan, ṣùgbọ́n ̀kan ni Ọlọ́run.

21 3.21: Ro 8.2-4. Nítorí náà òfin ha lòdì àwọn ìlérí Ọlọ́run ? a i; nítorí ìbá ṣe a ti fi òfin kan fún ni ó lágbára láti sọ ni di ààyè nítòótọ́ òdodo ìbá ti tipasẹ̀ òfin . 22 3.22: Ro 3.9-19; 11.32.Ṣùgbọ́n ìwé mímọ́ ti fi wa gbogbo ènìyàn ni ń bẹ lábẹ́ ìdè ̀ṣẹ̀, a fi ìlérí nípa ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi fún àwọn ó gbàgbọ́.

Ọmọ Ọlọ́run

23 Ṣùgbọ́n ìgbàgbọ́ , a ti pa mọ́ lábẹ́ òfin, a wa mọ́ de ìgbàgbọ́ a ń bọ̀ fihàn. 24 Nítorí náà òfin ti jẹ́ olùtọ́láti ènìyàn sọ́dọ̀ Kristi, a wa láre nípa ìgbàgbọ́. 25 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà ìgbàgbọ́ ti , àwa lábẹ́ olùtọ́mọ́.

26 Nítorí ọmọ Ọlọ́run ni gbogbo yín, nípa ìgbàgbọ́ nínú Kristi Jesu. 27 Nítorí iye ̀yin a ti bamitiisi sínú Kristi ti gbé Kristi wọ̀. 28 3.28: Ro 10.12.le Júù tàbí Giriki, ẹrú tàbí òmìnira, ọkùnrin tàbí obìnrin nítorí ̀kan ni nínú Kristi Jesu. 29 ̀yin jẹ́ ti Kristi, ǹjẹ́ ̀yin irú-ọmọ Abrahamu, àti àrólé gẹ́gẹ́ ìlérí.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-