Publicidade

Hebreus 10

Ìrúbọ Kristi lẹ́̀kan ṣoṣo fún gbogbo ènìyàn

1 Nítorí òfin jẹ́ òjìji àwọn ohun rere ti ń bọ̀ í ṣe àwòrán tòótọ́ fún àwọn òtítọ́ náà, wọn fi ẹbọ kan náà wọn ń nígbà gbogbo lọ́dọọdún mu àwọn ń jọ́sìn di pípé. 2 ṣe bẹ́̀, a ìbá dẹ́kun àti máa wọn, nítorí àwọn ti ń sìn ki ìbá ìmọ̀ ̀ṣẹ̀, nígbà a ti wẹ̀ wọ́n mọ́ lẹ́̀kan ṣoṣo. 3 Ṣùgbọ́n nínú ẹbọ wọ̀nyí ni a ń ṣe ìrántí ̀ṣẹ̀ lọ́dọọdún. 4 Nítorí ko ṣe é ṣe fún ̀jẹ̀ akọ màlúù àti ti ewúrẹ́ láti ̀ṣẹ̀ kúrò.

5 10.5-9: Sm 40.6-8. Nítorí náà nígbà Kristi ayé, ó ,

"Ìwọ fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ,

ṣùgbọ́n ara ni ìwọ ti pèsè fún mi,

6 ẹbọ sísun àti ẹbọ fún ̀ṣẹ̀ ni

ìwọ inú dídùn .

7 Nígbà náà ni mo , Kíyèsi i (nínú ìwé kíká ni a gbé kọ ́ nípa ti èmi)

mo láti ṣe ìfẹ́ rẹ, Ọlọ́run.’ "

8 Nígbà o ni ìṣáájú , "Ìwọ fẹ́ ẹbọ àti ọrẹ àti ẹbọ sísun, àti ẹbọ fún ̀ṣẹ̀, bẹ́̀ ni ìwọ ni inú dídùn si wọn" (àwọn èyí a ń gẹ́gẹ́ òfin). 9 Nígbà náà ni ó , "Kíyèsi i, mo de láti ṣe ìfẹ́ rẹ Ọlọ́run." Ó ti ìṣáájú kúrò, a fi ìdí èkejì múlẹ̀. 10 Nípa ìfẹ́ náà ni a ti sọ di mímọ́ nípa ẹbọ ti Jesu Kristi fi ara rẹ̀ lẹ́̀kan ṣoṣo.

11 Àti olúkúlùkù àlùfáà ń dúró lójoojúmọ́ láti ṣiṣẹ́ ìsìn, ó ń ṣe ẹbọ kan náà nígbàkígbà, ̀ṣẹ̀ kúrò láé. 12 10.12-13: Sm 110.1.Ṣùgbọ́n òun, lẹ́yìn ìgbà o ti ẹbọ kan fún ̀ṣẹ̀ títí láé, o jókòó lọ́wọ́ ̀tún Ọlọ́run; 13 láti ìgbà náà, ó retí títí a o fi àwọn ̀rẹ̀ ṣe àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀. 14 Nítorí nípa ẹbọ kan a ti àwọn a sọ di mímọ́ títí láé.

15 ̀Mímọ́ ń jẹ́rìí fún wa pẹ̀, nítorí lẹ́yìn ó ,

16 10.16-17: Jr 31.33-34. "Èyí ni májẹ̀ti èmi o ba wọn

lẹ́hìn àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ni Olúwa .

Èmi o fi òfin mi wọn ọkàn,

inú wọn pẹ̀ni èmi o kọ wọn ."

17 Ó tún sọ :

"̀ṣẹ̀ wọn àti àìṣedéédéé wọn

lèmi yóò rántí mọ́."

18 Ṣùgbọ́n níbi ìmúkúrò ìwọ̀nyí gbé , ìrúbọ fún ̀ṣẹ̀ mọ́.

Ìpè ìforítì

19 Ará, ǹjẹ́ a ti ìgboyà láti wọ inú Ibi Mímọ́ Jùlọ nípasẹ̀ ̀jẹ̀ Jesu, 20 nípa ̀títún àti ààyè, o mímọ́ fún wa, àti láti kọjá aṣọ ìkélé èyí yìí , ara rẹ̀; 21 àti a ti ni àlùfáà gíga lórí ilé Ọlọ́run; 22 jẹ́ a fi òtítọ́ ọkàn súnmọ́ tòsí ni ̀kún ìgbàgbọ́, a wẹ ọkàn wa mọ́ kúrò nínú ̀ọkàn búburú, a fi omi mímọ́ wẹ ara wa . 23 jẹ́ a di ìjẹ́wọ́ ìrètí wa mu ṣinṣin ni àìṣiyèméjì, nítorí olóòtítọ́ ẹni o ṣe ìlérí. 24 jẹ́ a yẹ ara wa láti ru ara wa ìfẹ́ àti iṣẹ́ rere, 25 a ma máa kọ ìpéjọpọ̀ ara wa sílẹ̀, gẹ́gẹ́ bi àṣà àwọn ẹlòmíràn; ṣùgbọ́n a máa gba ara ẹni níyànjú pẹ̀lúpẹ̀̀yin ti i ọjọ́ náà ń súnmọ́ etílé.

26 Nítorí àwa ba mọ̀ ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ lẹ́yìn ìgbà àwa ti gba ìmọ̀ òtítọ́ tún ẹbọ fún ̀ṣẹ̀ mọ́. 27 10.27: Isa 26.11.ṣe ìrètí ìdájọ́ ó ba ni lẹ́, àti ti ìbínú ti o múná, yóò pa àwọn ̀run. 28 10.28: De 17.2-6.Ẹnikẹ́ni ó ba gan òfin Mose, ó láìsí àánú nípa ̀ẹni méjì tàbí mẹ́ta. 29 10.29: El 24.8.Mélòó mélòó ni a o jẹ ẹni náà ìyà kíkan, ẹni o tẹ Ọmọ Ọlọ́run mọ́lẹ̀ ó ti ka ̀jẹ̀ májẹ̀ti a fi sọ ́ di mímọ́ si ohun àìmọ́, ó ti kẹ́gàn ̀oore-ọ̀fẹ́. 30 10.30: De 32.35-36.Nítorí àwa mọ ẹni o , ̀san ni ti èmi, Olúwa , "Èmi ó gbẹ̀san." Àti pẹ̀, "Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀." 31 Ohun ̀ni láti ṣubú ọwọ́ Ọlọ́run alààyè.

32 Ṣùgbọ́n rántí ọjọ́ ìṣáájú nínú èyí , nígbà a ti yin lójú, fi ara da wàhálà ńlá ti ìjìyà; 33 lápákan, nígbà a sọ yín di ìran wíwò nípa ̀gàn àti ìpọ́njú; àti lápákan, nígbà ̀yin di ẹgbẹ́ àwọn a ṣe bẹ́̀ si. 34 Nítorí ̀yin àwọn ó nínú ìdè kẹ́dùn, fi ayọ̀ gba ìkólọ ẹrù yin, nítorí ̀yin mọ nínú ara yin , ni ọrọ̀ ó títí, ó dára bẹ́̀ lọ. 35 Nítorí náà ṣe gbé ìgboyà yín sọnù, èyí ti o ni èrè ńlá.

36 Nítorí ̀yin le ṣe aláìní sùúrù, nítorí ìgbà ̀yin ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan ̀yin le gba ìlérí náà. 37 10.37: Isa 26.20; Hk 2.3-4.Nítorí,

"Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ i,

ẹni náà ti ń bọ̀ yóò ,

yóò jáfara.

38 Ṣùgbọ́n,

"Olódodo ni yóò nípa ìgbàgbọ́.

Ṣùgbọ́n o ba fàsẹ́yìn,

ọkàn mi inú dídùn i."

39 Ṣùgbọ́n àwa nínú àwọn ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; ṣe nínú àwọn o gbàgbọ́ ìgbàlà ọkàn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_15-35-42-