Publicidade

Hebreus 11

Nípa ìgbàgbọ́

1 Ǹjẹ́ ìgbàgbọ́ ìdánilójú ohun o ń retí, ìjẹ́rìí ohun a . 2 Nítorí nínú rẹ ni àwọn alàgbà àtijọ́ ̀rere.

3 Nípa ìgbàgbọ́ ni a mọ̀ a ti ayé nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run; nítorí náà í ṣe ohun o hàn ni a fi ohun a ń ri.

4 Nípa ìgbàgbọ́ Abeli ẹbọ Ọlọ́run ó sàn ju ti Kaini lọ, nípa èyí a jẹ́rìí rẹ̀ pe olódodo ni, Ọlọ́run ń jẹ́rìí ̀bùn rẹ̀, àti nípa rẹ̀ náà, o ti jẹ́ o ti , síbẹ̀ o ń fọhùn.

5 Nípa ìgbàgbọ́ ni a ṣí Enoku ipò padà o ṣe ikú; a i mọ́, nítorí Ọlọ́run ṣí i ipò padà ṣáájú ìṣípò padà rẹ̀, a jẹ́rìí yìí i o wu Ọlọ́run. 6 Ṣùgbọ́n láìsí ìgbàgbọ́ ṣe é ṣe láti ú; nítorí ẹni ó ń tọ Ọlọ́run ṣàì gbàgbọ́ ó ń bẹ, àti òun olùṣẹ̀san fún àwọn o fi ara balẹ̀ a.

7 Nípa ìgbàgbọ́ ni Noa, nígbà ti Ọlọ́run, kìlọ̀ ohun a kóò ì fún un, o bẹ̀Ọlọ́run ó kan ọkọ̀ fún ìgbàlà ilé rẹ̀, nípa èyí ó da ayé lẹ́bi, ó di ajogún òdodo i ṣe nípa ìgbàgbọ́.

8 Nípa ìgbàgbọ́ Abrahamu, nígbà a ti e láti jáde lọ ibi òun yóò gbà fún ilẹ̀ ìní, ó gbọ́, ó jáde lọ, láì mọ ibi òun ń . 9 Nípa ìgbàgbọ́ o ṣe àtìpó ilẹ̀ ìlérí, ẹni ni ilẹ̀ àjèjì, o ń gbé inú àgọ́, pẹ̀Isaaki àti Jakọbu, àwọn ajogún ìlérí kan náà pẹ̀rẹ̀, 10 nítorí ó ń retí ìlú ó ìpìlẹ̀; èyí Ọlọ́run tẹ̀ó kọ́. 11 Nípa ìgbàgbọ́ ni Sara tìkára rẹ̀ pẹ̀fi gba agbára láti lóyún, nígbà ó kọjá ìgbà rẹ̀, nítorí o ka ẹni o ṣe ìlérí olóòótọ́. 12 Nítorí náà ni ̀pọ̀lọpọ̀ ṣe ti ara ọkùnrin kan jáde, àní ara ẹni o dàbí òkú, ọmọ ìràwọ̀ ojú ̀run lọ́pọ̀lọ́pọ̀, àti iyanrìn etí Òkun láìníye.

13 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ó nínú ìgbàgbọ́, láìrí àwọn ìlérí náà gbà, ṣùgbọ́n wọn wọn ni òkèrè réré, wọ́n gbá wọn , wọ́n jẹ́wọ́ àlejò àti àjèjì ni àwọn lórí ilẹ̀ ayé. 14 Nítorí àwọn o ń sọ irú ohun bẹ́̀ fihàn gbangba , wọn ń ṣe àfẹ́ìlú kan i ṣe tiwọn. 15 Àti nítòótọ́, ìbá ṣe wọ́n fi ìlú tiwọn jáde ọkàn, wọn ìbá ti ààyè padà. 16 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n ń fẹ́ ìlú kan o dára bẹ́̀ lọ, èyí yìí ni ti ̀run, nítorí náà ojú wọn ti Ọlọ́run, a máa òun ni Ọlọ́run wọn; nítorí o ti pèsè ìlú kan sílẹ̀ fún wọn.

17 Nípa ìgbàgbọ́ ni Abrahamu, nígbà a dán an láti, fi Isaaki ẹbọ: àní òun ẹni ó ìlérí gba múra tan láti fi ọmọ bíbí rẹ kan ṣoṣo ẹbọ. 18 Nípa ẹni , "Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀." 19 Ó ó si Ọlọ́run tilẹ̀ gbé e dìde kúrò nínú òkú, bẹ́̀ ni, a sọ ́ lọ́àpẹẹrẹ, ó gbà á padà.

20 Nípa ìgbàgbọ́ Isaaki súre fún Jakọbu àti Esau ti ohun ń bọ̀.

21 Nípa ìgbàgbọ́ ni Jakọbu, nígbà o ń ku lọ, ó súre fún àwọn ọmọ Josẹfu ni ̀kọ̀̀kan; ó sinmi ìtẹríba orí ̀rẹ̀.

22 Nípa ìgbàgbọ́ ni Josẹfu, nígbà ó ń ku lọ, ó rántí ìjáde lọ àwọn ọmọ Israẹli; ó pàṣẹ ti àwọn egungun rẹ̀.

23 Nípa ìgbàgbọ́ àwọn òbí Mose pa a mọ́ fún oṣù mẹ́ta nígbà a i, nítorí tiwọn i arẹwà ọmọ; wọn bẹ̀àṣẹ ọba.

24 Nípa ìgbàgbọ́ ni Mose, nígbà o dàgbà, ó kọ̀ ki a máa òun ni ọmọ ọmọbìnrin Farao; 25 o kúkú yàn láti máa ba àwọn ènìyàn Ọlọ́run jìyà, ju jíjẹ fàájì ̀ṣẹ̀ fún ìgbà díẹ̀. 26 Ó ka ̀gàn Kristi si ọrọ̀ ó pọ̀àwọn ìṣúra Ejibiti lọ, nítorí ó ń wo èrè náà. 27 Nípa ìgbàgbọ́ ni o kọ Ejibiti sílẹ̀ láìbẹ̀ìbínú ọba: nítorí o dúró ṣinṣin ẹni ó n ri ẹni àìrí. 28 Nípa ìgbàgbọ́ ni ó da àsè ìrékọjá sílẹ̀, àti ìbùwọ́n ̀jẹ̀, ẹni ń pa àwọn àkọ́ọmọ a fi ọwọ́ kan wọn.

29 Nípa ìgbàgbọ́ ni wọn la òkun pupa kọjá bi ẹni ni ìyàngbẹ ilẹ̀ ni: ti àwọn ara Ejibiti dánwò, wọ́n ri.

30 Nípa ìgbàgbọ́ ni àwọn odi Jeriko wo lulẹ̀, lẹ́yìn ìgbà a wọn ni ọjọ́ méje.

31 Nípa ìgbàgbọ́ ni Rahabu panṣágà ṣègbé pẹ̀àwọn gbọ́rọ̀ nígbà o tẹ́wọ́gbà àwọn àmì àlàáfíà.

32 Èwo ni èmi o tún máa i? Nítorí ìgbà yóò kùnà fún mi láti sọ ti Gideoni, àti Baraki, àti Samsoni, àti Jefta; àti Dafidi, àti Samuẹli, àti ti àwọn wòlíì, 33 àwọn ẹni nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ tiwọn ṣẹ́gun ilẹ̀ ọba, wọn ṣiṣẹ́ òdodo, tiwọn gba ìlérí, tiwọn àwọn kìnnìún lénu, 34 wọ́n pa agbára iná, wọ́n bọ́ lọ́wọ́ ojú idà, a sọ di alágbára nínú àìlera, wọ́n akọni nínú ìjà, wọ́n ogun àwọn àjèjì . 35 Àwọn obìnrin ri òkú wọn gbà nípa àjíǹde: a da àwọn ẹlòmíràn lóró, wọ́n kọ̀ láti gba ìdásílẹ̀; wọn ba àjíǹde o dára gbà. 36 Àwọn ẹlòmíràn ìjìyà ̀sín, àti nínà, àti ju bẹ́̀ lọ, ti ìdè àti ti túbú. 37 A sọ wọ́n ni òkúta, a fi ayùn rẹ́ wọn méjì, a dán wọn a fi idà pa wọn, wọ́n rìn káàkiri nínú awọ àgùntàn àti nínú awọ ewúrẹ́; wọn di aláìní, olùpọ́njú, ẹni a ń da lóró; 38 àwọn ẹni ayé ko yẹ fún. Wọ́n ń kiri nínú aṣálẹ̀, àti lórí òkè, àti nínú ihò àti nínú abẹ́ ilẹ̀.

39 Gbogbo àwọn wọ̀nyí a jẹ́rìí rere nípa ìgbàgbọ́, wọn ìlérí náà gbà, 40 nítorí Ọlọ́run ti pèsè ohun ó dára sílẹ̀ fún wa, láìsí wa, a ṣe wọn .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-