Pular para o conteúdo
Publicidade

Hebreus 12

10 Nítorí wọ́n tọ́ wa fún ọjọ́ díẹ̀ o ti dára lójú wọn; ṣùgbọ́n Òun tọ́ wa fún èrè wa, àwa ṣe alábápín ìwà mímọ́ rẹ̀. 11 Gbogbo ìbáwí dàbí ohun ayọ̀ nísinsin yìí ṣe ìbànújẹ́; ṣùgbọ́n níkẹyìn yóò so èso àlàáfíà fún àwọn a tọ́ nípa rẹ̀, àní èso òdodo.

Veja também