Publicidade

Hebreus 12

Ìbáwí àwọn Ọmọ Ọlọ́run

1 Nítorí náà a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí báyìí wa , jẹ́ a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo apá kan, àti ̀ṣẹ̀ o rọrùn láti di mọ́ wa, a máa fi sùúrù súré ìje a gbé ka iwájú wa, 2 a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ a gbé ka iwájú rẹ, o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú , ó jókòó lọ́wọ́ ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run. 3 Máa ro ti ẹni ó faradà irú ìsọ̀rọ̀-òdì yìí láti ̀dọ̀ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ si ara rẹ̀, ba á rẹ̀wẹ̀ni ọkàn yín, àárẹ̀ si mu yín.

4 ̀yin à ì kọ ojú ìjà si ̀ṣẹ̀ títí títa ̀jẹ̀ yín sílẹ̀ nínú ìjàkadì yín. 5 ̀yin ti gbàgbé ̀rọ̀ ìyànjú ó n ba yin sọ̀rọ̀ ọmọ ,

"Ọmọ mi, ma ṣe aláìnání ìbáwí Olúwa,

o ṣe rẹ̀wẹ̀nígbà a ń ti ọwọ́ rẹ̀ ba ,

6 nítorí ẹni ti Olúwa fẹ́, òun ni i ,

a máa na olúkúlùkù ọmọ òun tẹ́wọ́gbà."

7 máa sùúrù lábẹ́ ìbáwí, Ọlọ́run wa ọmọ ni; nítorí ọmọ wo ni ń bẹ ti baba í ? 8 Ṣùgbọ́n ̀yin ba láìsí ìbáwí, nínú èyí gbogbo ènìyàn ti jẹ alábápín, ǹjẹ́ ọmọ àlè ni yín, í ṣe ọmọ. 9 Pẹ̀lúpẹ̀àwa ni baba wa nípa ti ara o ń tọ́ wa, àwa ń bu ọlá fún wọn: ha yẹ a kúkú tẹríba fún Baba àwọn ̀, a ? 10 Nítorí wọ́n tọ́ wa fún ọjọ́ díẹ̀ o ti dára lójú wọn; ṣùgbọ́n Òun tọ́ wa fún èrè wa, àwa ṣe alábápín ìwà mímọ́ rẹ̀. 11 Gbogbo ìbáwí dàbí ohun ayọ̀ nísinsin yìí ṣe ìbànújẹ́; ṣùgbọ́n níkẹyìn yóò so èso àlàáfíà fún àwọn a tọ́ nípa rẹ̀, àní èso òdodo.

12 Nítorí náà, na ọwọ́ ó rọ, àti eékún àìlera, 13 "ṣe ipa ̀ó tọ́ fún ẹsẹ̀ yin," èyí ó rọ a kúrò lórí ike ṣùgbọ́n a kúkú ó sàn.

Ìkìlọ̀ lòdì kíkọ Ọlọ́run

14 máa lépa àlàáfíà pẹ̀ènìyàn gbogbo, àti ìwà mímọ́, láìsí èyí yìí ẹni yóò Olúwa. 15 máa kíyèsára ẹnikẹ́ni ṣe kùnà Oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run; gbòǹgbò ìkorò kan máa ba sókè ó yọ yín lẹ́nu, ̀pọ̀lọpọ̀ a ti ipa rẹ̀ di àìmọ́. 16 o à si àgbèrè kan tàbí aláìwà-bí-Ọlọ́run bi Esau, ẹni o tìtorí òkèlè oúnjẹ kan ta ogún ìbí rẹ̀. 17 Nítorí ̀yin mọ lẹ́yìn náà, nígbà ó fẹ́ láti jogún ìbùkún náà, a kọ̀ ́, nítorí ri ààyè ìrònúpìwàdà, o tilẹ̀ jẹ́ ó fi omijé wa a gidigidi.

18 Nítorí ̀yin òkè a fi ọwọ́ kàn, àti ti iná ti ń , àti ti ìṣúdudu àti òkùnkùn, àti ìjì. 19 Àti ìró ìpè, àti ohùn ̀rọ̀, èyí àwọn o gbọ́ bẹ̀bẹ̀ , a ṣe sọ ̀rọ̀ i fún wọn mọ́, 20 nítorí wọn gba ohun ó paláṣẹ, "o tilẹ̀ jẹ ẹranko ni ó fi ara kan òkè náà, a ó sọ ́ ni òkúta." 21 Ìran náà lẹ́to bẹ́̀ Mose , "̀ba mi gidigidi mo wárìrì."

22 Ṣùgbọ́n ̀yin òkè Sioni, àti ìlú Ọlọ́run alààyè, ti Jerusalẹmu ti ̀run, àti si ẹgbẹ́ àwọn angẹli àìníye, 23 si àjọ ńlá ìjọ àkọ́a ti kọ orúkọ wọn ni ̀run, àti sọ́dọ̀ Ọlọ́run onídàájọ́ gbogbo ènìyàn, àti sọ́dọ̀ àwọn ̀olóòtítọ́ ènìyàn a ṣe ni àṣepé, 24 àti sọ́dọ̀ Jesu alárinà májẹ̀tuntun, àti si ibi ̀jẹ̀ ìbùwọ́n ni, ti ń sọ̀rọ̀ ohun ó dára ju ti Abeli lọ.

25 Kíyèsi i, ṣe kọ̀ ẹni ń kìlọ̀. Nítorí àwọn wọ̀nyí bọ́ nígbà wọn kọ̀ ẹni ti ń kìlọ̀ ni ayé, mélòó mélòó ni àwa yóò bọ́, àwa ba pẹ̀yìndà ẹni ń kìlọ̀ láti ̀run , 26 ohùn ẹni ó mi ayé nígbà náà, ṣùgbọ́n nísinsin yìí o ti ṣe ìlérí, , "Lẹ́̀kan i èmi ki yóò mi kìkì ayé nìkan, ṣùgbọ́n ̀run pẹ̀." 27 Àti ̀rọ̀ yìí, "Lẹ́̀kan i," ìtumọ̀ rẹ̀ ni, mímú àwọn ohun wọ̀nyí ti a ń kúrò, ohun a ti , àwọn ohun a síbẹ̀.

28 Nítorí náà àwa ń gbà ilẹ̀ ọba ti a , jẹ́ a ọpẹ́ nípa èyí ti a fi máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀̀wọ̀ àti ìbẹ̀rẹ̀. 29 Nítorí , "Ọlọ́run wa, iná ti ń ni run ni."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-