Publicidade

Judas 1

1 Juda, ìránṣẹ́ Jesu Kristi àti arákùnrin Jakọbu,

àwọn a , olùfẹ́ nínú Ọlọ́run Baba, a pamọ́ fún Jesu Kristi:

2 àánú, àlàáfíà àti ìfẹ́ ó máa jẹ́ tiyín ̀pọ̀lọpọ̀.

̀ṣẹ̀ àti ìparun àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run

3 ̀yin ̀rẹ́ mi tòótọ́, ó tilẹ̀ jẹ́ èmí ìtara láti kọ̀i yín nípa ìgbàlà í ṣe ti gbogbo ènìyàn, n gbọdọ̀ kọ̀yín, ń gbà yín ìyànjú láti máa fitafita fún ìgbàgbọ́, a ti fi àwọn ènìyàn mímọ́ lọ́wọ́ ̀̀kan ṣoṣo. 4 Nítorí àwọn ènìyàn kan ń bẹ wọ́n ń yọ́ wọlé, àwọn ẹni a ti yàn láti ìgbà àtijọ́ ̀bi yìí, àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run, ń oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run wa padà wọ̀bìà, wọn ń sẹ́ Olúwa wa kan ṣoṣo náà, àní, Jesu Kristi Olúwa.

5 Nítòótọ́, ti mọ nǹkan wọ̀nyí ̀̀kan , mo fẹ́ rán an yín létí , lẹ́yìn Olúwa ti gba àwọn kan láti ilẹ̀ Ejibiti , lẹ́yìn náà ni ó run àwọn gbàgbọ́. 6 Àti àwọn angẹli tọ́ipò ọlá wọn, ṣùgbọ́n wọn fi ipò wọn sílẹ̀, àwọn ó pamọ́ sínú ̀wọ̀n àìnípẹ̀kun ìsàlẹ̀ òkùnkùn de ìdájọ́ ọjọ́ ńlá . 7 Àní Sodomu àti Gomorra, àti àwọn ìlú agbègbè wọn, ti fi ara wọn fún àgbèrè ṣíṣe, wọ́n ń tẹ̀ará àjèjì lẹ́yìn, àwọn ni ó fi lélẹ̀ àpẹẹrẹ, àwọn ó ń jìyà iná àìnípẹ̀kun.

8 Bákan náà ni àwọn wọ̀nyí ń sọ ara wọn di èérí nínú àlá wọn, wọ́n ń gan ìjòyè, wọn ń sọ̀rọ̀ búburú àwọn ọlọ́. 9 Ṣùgbọ́n Mikaeli, olórí àwọn angẹli, nígbà ó ń Èṣù jiyàn nítorí òkú Mose, sọ ̀rọ̀-òdì i; ṣùgbọ́n ó , "Olúwa ." 10 Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí n sọ̀rọ̀-òdì ohun gbogbo ti wọn: ṣùgbọ́n ohun gbogbo wọn mọ̀ nípa èrò ara ni, ẹranko ìyè, nípasẹ̀ nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n di ẹni ìparun.

11 Ègbé ni fún wọn! Nítorí wọ́n ti rìn ̀Kaini, wọ́n fi ìwọra súré sínú ìṣìnà Balaamu nítorí ère, wọn ṣègbé nínú ìṣọ̀tẹ̀ Kora.

12 Àwọn wọ̀nyí ó jẹ́ àbàwọ́n nínú àsè ìfẹ́ yín, nígbà wọ́n ń yín jẹ àsè, àwọn olùṣọ́-àgùntàn ti ń bọ́ ara wọn láìbẹ̀. Wọ́n jẹ́ ìkùùkuu láìrọ òjò, a ń ti ọwọ́ afẹ́fẹ́ gbá kiri; àwọn igi aláìléso àkókò èso, wọ́n lẹ́̀méjì, a wọ́n tigbòǹgbò tigbòǹgbò. 13 Wọ́n jẹ́ ìjì líle ti ń ru ojú omi Òkun, ti ń ìfófó ìtìjú wọn jáde; alárìnkiri ìràwọ̀, àwọn a pa òkùnkùn biribiri mọ́ láéláé.

14 Àwọn wọ̀nyí pẹ̀ni Enoku, ẹni keje láti ̀dọ̀ Adamu, sọtẹ́lẹ̀ nípa wọn , "Kíyèsi i, Olúwa ń bọ̀ pẹ̀ẹgbẹẹgbẹ̀rún ̀ẹgbẹ̀rún àwọn ènìyàn rẹ̀ mímọ́, 15 láti ṣe ìdájọ́ gbogbo ènìyàn, láti gbogbo àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run lẹ́bi ti gbogbo iṣẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run wọn, ti wọ́n ti fi àìwà-bí-Ọlọ́run ṣe, àti ti gbogbo ̀rọ̀ líle àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ aláìwà-bí-Ọlọ́run ti sọ i." 16 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí àwọn ti ń kùn, àwọn aláròyé, ti ń rìn nípa ìfẹ́kúfẹ̀́ ara wọn; wọn ń gbéraga nípa ara wọn, wọ́n ń ṣátá àwọn ènìyàn mìíràn fún èrè ara wọn.

Ìpè fún ìdúró ṣinṣin

17 Ṣùgbọ́n ̀yin olùfẹ́, rántí àwọn ̀rọ̀ a ti sọ ṣáájú láti ọwọ́ àwọn aposteli Olúwa wa Jesu Kristi. 18 wọn ti fún yín , "Nígbà ìkẹyìn àwọn ẹlẹ́gàn yóò , wọn yóò máa rìn gẹ́gẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ àìwà-bí-Ọlọ́run ti ara wọn." 19 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ni àwọn ẹni ń ya ara wọn ̀tọ̀, àwọn ẹni ti ara, wọn ni ̀.

20 Ṣùgbọ́n ̀yin, olùfẹ́, ti ń gbé ara yín lórí ìgbàgbọ́ yín ó mọ́ jùlọ, ti ń gbàdúrà nínú ̀Mímọ́. 21 máa pa ara yín mọ́ nínú ìfẹ́ Ọlọ́run, ̀yin ti ń retí àánú Olúwa wa Jesu Kristi yóò yín ìyè àìnípẹ̀kun.

22 máa ṣàánú fún àwọn ń ṣe iyèméjì. 23 máa gba àwọn ẹlòmíràn , nípa fífà wọ́n yọ kúrò nínú iná; máa ṣàánú pẹ̀ìbẹ̀kórìíra ̀ara ti sọ di èérí.

Orin ìyìn Ọlọ́run

24 Ǹjẹ́ mo fi yín ẹni o pa yín mọ́ kúrò nínú ìkọ̀sẹ̀, o yín síwájú ògo rẹ̀ láìlábùkù pẹ̀ayọ̀ ńlá lọ́wọ́— 25 Ọlọ́run ọlọ́gbọ́n nìkan ṣoṣo, Olùgbàlà wa, ògo àti ọláńlá, ìjọba àti agbára, nípasẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, gbogbo ayé , nísinsin yìí àti títí láéláé! Àmín.

Veja também

Publicidade
Judas
Ver todos os capítulos de Judas
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-