Publicidade

Judas 1

1 Juda, ìránṣẹ́ Jesu Kristi àti arákùnrin Jakọbu,

àwọn a , olùfẹ́ nínú Ọlọ́run Baba, a pamọ́ fún Jesu Kristi:

2 àánú, àlàáfíà àti ìfẹ́ ó máa jẹ́ tiyín ̀pọ̀lọpọ̀.

̀ṣẹ̀ àti ìparun àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run

3 ̀yin ̀rẹ́ mi tòótọ́, ó tilẹ̀ jẹ́ èmí ìtara láti kọ̀i yín nípa ìgbàlà í ṣe ti gbogbo ènìyàn, n gbọdọ̀ kọ̀yín, ń gbà yín ìyànjú láti máa fitafita fún ìgbàgbọ́, a ti fi àwọn ènìyàn mímọ́ lọ́wọ́ ̀̀kan ṣoṣo. 4 4-16: 2Pt 2.1-18.Nítorí àwọn ènìyàn kan ń bẹ wọ́n ń yọ́ wọlé, àwọn ẹni a ti yàn láti ìgbà àtijọ́ ̀bi yìí, àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run, ń oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run wa padà wọ̀bìà, wọn ń sẹ́ Olúwa wa kan ṣoṣo náà, àní, Jesu Kristi Olúwa.

5 Nítòótọ́, ti mọ nǹkan wọ̀nyí ̀̀kan , mo fẹ́ rán an yín létí , lẹ́yìn Olúwa ti gba àwọn kan láti ilẹ̀ Ejibiti , lẹ́yìn náà ni ó run àwọn gbàgbọ́. 6 Àti àwọn angẹli tọ́ipò ọlá wọn, ṣùgbọ́n wọn fi ipò wọn sílẹ̀, àwọn ó pamọ́ sínú ̀wọ̀n àìnípẹ̀kun ìsàlẹ̀ òkùnkùn de ìdájọ́ ọjọ́ ńlá . 7 7: Gẹ 19.Àní Sodomu àti Gomorra, àti àwọn ìlú agbègbè wọn, ti fi ara wọn fún àgbèrè ṣíṣe, wọ́n ń tẹ̀ará àjèjì lẹ́yìn, àwọn ni ó fi lélẹ̀ àpẹẹrẹ, àwọn ó ń jìyà iná àìnípẹ̀kun.

8 Bákan náà ni àwọn wọ̀nyí ń sọ ara wọn di èérí nínú àlá wọn, wọ́n ń gan ìjòyè, wọn ń sọ̀rọ̀ búburú àwọn ọlọ́. 9 9: Sk 3.2.Ṣùgbọ́n Mikaeli, olórí àwọn angẹli, nígbà ó ń Èṣù jiyàn nítorí òkú Mose, sọ ̀rọ̀-òdì i; ṣùgbọ́n ó , "Olúwa ." 10 Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí n sọ̀rọ̀-òdì ohun gbogbo ti wọn: ṣùgbọ́n ohun gbogbo wọn mọ̀ nípa èrò ara ni, ẹranko ìyè, nípasẹ̀ nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n di ẹni ìparun.

11 11: Gẹ 4.3-8; Nu 22.24; 16. Ègbé ni fún wọn! Nítorí wọ́n ti rìn ̀Kaini, wọ́n fi ìwọra súré sínú ìṣìnà Balaamu nítorí ère, wọn ṣègbé nínú ìṣọ̀tẹ̀ Kora.

12 Àwọn wọ̀nyí ó jẹ́ àbàwọ́n nínú àsè ìfẹ́ yín, nígbà wọ́n ń yín jẹ àsè, àwọn olùṣọ́-àgùntàn ti ń bọ́ ara wọn láìbẹ̀. Wọ́n jẹ́ ìkùùkuu láìrọ òjò, a ń ti ọwọ́ afẹ́fẹ́ gbá kiri; àwọn igi aláìléso àkókò èso, wọ́n lẹ́̀méjì, a wọ́n tigbòǹgbò tigbòǹgbò. 13 Wọ́n jẹ́ ìjì líle ti ń ru ojú omi Òkun, ti ń ìfófó ìtìjú wọn jáde; alárìnkiri ìràwọ̀, àwọn a pa òkùnkùn biribiri mọ́ láéláé.

14 14: Gẹ 5.18,21-24. Àwọn wọ̀nyí pẹ̀ni Enoku, ẹni keje láti ̀dọ̀ Adamu, sọtẹ́lẹ̀ nípa wọn , "Kíyèsi i, Olúwa ń bọ̀ pẹ̀ẹgbẹẹgbẹ̀rún ̀ẹgbẹ̀rún àwọn ènìyàn rẹ̀ mímọ́, 15 láti ṣe ìdájọ́ gbogbo ènìyàn, láti gbogbo àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run lẹ́bi ti gbogbo iṣẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run wọn, ti wọ́n ti fi àìwà-bí-Ọlọ́run ṣe, àti ti gbogbo ̀rọ̀ líle àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ aláìwà-bí-Ọlọ́run ti sọ i." 16 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí àwọn ti ń kùn, àwọn aláròyé, ti ń rìn nípa ìfẹ́kúfẹ̀́ ara wọn; wọn ń gbéraga nípa ara wọn, wọ́n ń ṣátá àwọn ènìyàn mìíràn fún èrè ara wọn.

Ìpè fún ìdúró ṣinṣin

17 Ṣùgbọ́n ̀yin olùfẹ́, rántí àwọn ̀rọ̀ a ti sọ ṣáájú láti ọwọ́ àwọn aposteli Olúwa wa Jesu Kristi. 18 18: 2Pt 3.3.wọn ti fún yín , "Nígbà ìkẹyìn àwọn ẹlẹ́gàn yóò , wọn yóò máa rìn gẹ́gẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ àìwà-bí-Ọlọ́run ti ara wọn." 19 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ni àwọn ẹni ń ya ara wọn ̀tọ̀, àwọn ẹni ti ara, wọn ni ̀.

20 Ṣùgbọ́n ̀yin, olùfẹ́, ti ń gbé ara yín lórí ìgbàgbọ́ yín ó mọ́ jùlọ, ti ń gbàdúrà nínú ̀Mímọ́. 21 máa pa ara yín mọ́ nínú ìfẹ́ Ọlọ́run, ̀yin ti ń retí àánú Olúwa wa Jesu Kristi yóò yín ìyè àìnípẹ̀kun.

22 máa ṣàánú fún àwọn ń ṣe iyèméjì. 23 23: Sk 3.3-4.máa gba àwọn ẹlòmíràn , nípa fífà wọ́n yọ kúrò nínú iná; máa ṣàánú pẹ̀ìbẹ̀kórìíra ̀ara ti sọ di èérí.

Orin ìyìn Ọlọ́run

24 Ǹjẹ́ mo fi yín ẹni o pa yín mọ́ kúrò nínú ìkọ̀sẹ̀, o yín síwájú ògo rẹ̀ láìlábùkù pẹ̀ayọ̀ ńlá lọ́wọ́— 25 Ọlọ́run ọlọ́gbọ́n nìkan ṣoṣo, Olùgbàlà wa, ògo àti ọláńlá, ìjọba àti agbára, nípasẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, gbogbo ayé , nísinsin yìí àti títí láéláé! Àmín.

Veja também

Judas
Ver todos os capítulos de Judas
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-