Publicidade

João 1

̀rọ̀ di ẹran-ara

1 àtètèkọ́ṣe ni ̀rọ̀ , ̀rọ̀ pẹ̀Ọlọ́run, Ọlọ́run ni ̀rọ̀ náà. 2 Òun ni ó pẹ̀Ọlọ́run àtètèkọ́ṣe. 3 Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ohun gbogbo; lẹ́yìn rẹ̀ a ohun kan nínú ohun a ti . 4 Nínú rẹ̀ ni ìyè , ìyè yìí náà ni ìmọ́lẹ̀ aráyé, 5 ìmọ́lẹ̀ náà ń mọ́lẹ̀ nínú òkùnkùn, òkùnkùn borí rẹ̀.

6 Ọkùnrin kan a rán láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ; orúkọ ẹni ń jẹ́ Johanu. 7 Òun ni a rán fún ̀, ó ṣe ẹlẹ́rìí fún ìmọ́lẹ̀ náà, gbogbo ènìyàn ó gbàgbọ́ nípasẹ̀ rẹ̀. 8 Òun fúnra rẹ̀ í ṣe ìmọ́lẹ̀ náà, ṣùgbọ́n a rán an láti ṣe ẹlẹ́rìí fún ìmọ́lẹ̀ náà.

9 Ìmọ́lẹ̀ òtítọ́ ń bẹ ń tan ìmọ́lẹ̀ fún olúkúlùkù ènìyàn ó ayé. 10 Òun ayé, àti , nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ti ayé, ṣùgbọ́n ayé mọ̀ ́n. 11 Ó tọ àwọn tirẹ̀ , àwọn tirẹ̀ gbà á. 12 Ṣùgbọ́n iye àwọn ó gbà á, àní àwọn náà ó gbà orúkọ rẹ̀ gbọ́, àwọn ni ó fi ̀tọ́ fún láti di ọmọ Ọlọ́run. 13 Àwọn ọmọ í ṣe nípa ̀jẹ̀, tàbí nípa ti ìfẹ́ ara, bẹ́̀ ni í ṣe nípa ìfẹ́ ti ènìyàn, ṣe láti ọwọ́ Ọlọ́run.

14 ̀rọ̀ náà di ara, òun ń wa gbé. Àwa ti ògo rẹ̀, àní ògo ọmọ rẹ kan ṣoṣo, ó ti ̀dọ̀ Baba , ó kún fún oore-ọ̀fẹ́ àti òtítọ́.

15 Johanu jẹ́rìí nípa rẹ̀, ó kígbe, ó , "Èyí ni ẹni mo sọ̀rọ̀ rẹ̀ , Ẹni ń bọ̀ lẹ́yìn mi pọ̀lọ, nítorí òun ti ṣáájú mi.’ " 16 Nítorí láti inú ̀kúnrẹ́rẹ́ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ ni gbogbo wa ti gba ìbùkún kún ìbùkún. 17 Nítorí nípasẹ̀ Mose ni a ti fi òfin fún ni ṣùgbọ́n òun; oore-ọ̀fẹ́ àti òtítọ́ láti ipasẹ̀ Jesu Kristi . 18 ẹni ó Ọlọ́run , ṣe òun nìkan, àní ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo, ẹni òun pàápàá jẹ́ Ọlọ́run, ó ìbáṣepọ̀ ó súnmọ́ jùlọ pẹ̀baba, òun náà ni ó fi í hàn.

Johanu sọ òun í ṣe Kristi

19 Èyí ni ̀Johanu, nígbà àwọn Júù rán àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi láti Jerusalẹmu láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ ẹni òun ń ṣe. 20 Òun kùnà láti jẹ́wọ́, ṣùgbọ́n òun jẹ́wọ́ wọ́́rọ́wọ́ , "Èmi í ṣe Kristi náà."

21 Wọ́n bi í léèrè , "Ta ha ni ìwọ? Elijah ni ìwọ ?"

Ó , "Èmi kọ́."

"Ìwọ ni wòlíì náà ?"

Ó dáhùn , "Bẹ́̀ kọ́."

22 ìparí wọ́n fún un , "Ta ni ìwọ í ṣe? Fún wa ìdáhùn àwa ó èsì padà tọ àwọn ó rán wa lọ. ni ìwọ nípa ti ara rẹ?"

23 Johanu fi ̀rọ̀ wòlíì Isaiah fún wọn èsì , "Èmi ni ohùn ẹni ń kígbe ijù, ṣe ̀Olúwa títọ́.’ "

24 ̀kan nínú àwọn Farisi a rán 25 bi í léèrè , "Èéṣe ìwọ fi ń bamitiisi nígbà náà, ìwọ í ṣe Kristi, tàbí Elijah, tàbí wòlíì náà?"

26 Johanu wọn lóhùn, , "Èmi ń fi omi bamitiisi, ẹnìkan dúró láàrín yín, ẹni ̀yin mọ̀, 27 Òun náà ni ẹni ń bọ̀ lẹ́yìn mi, okùn bàtà ẹni èmi láti ."

28 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó ṣẹlẹ̀ Betani òdìkejì odò Jordani, níbi Johanu ti ń fi omi bamitiisi.

Jesu jẹ́ ̀dọ́-Àgùntàn Ọlọ́run

29 ọjọ́ kejì, Johanu Jesu ó ń bọ̀ ̀dọ̀ rẹ̀, ó , "ó, ̀dọ́-àgùntàn Ọlọ́run, ẹni ó ̀ṣẹ̀ ayé lọ! 30 Èyí ni ẹni mo ń sọ nígbà mo , Ọkùnrin kan ń bọ̀ lẹ́yìn mi, ó pọ̀lọ, nítorí ó ti ṣáájú mi.31 Èmi gan an mọ̀ ́n, ṣùgbọ́n ìdí mo fi ń fi omi ṣe ìtẹ̀bọmi ni a fi í hàn fún Israẹli."

32 Nígbà náà ni Johanu jẹ́rìí i , "Mo ̀sọ̀kalẹ̀ láti ̀run àdàbà, ó e. 33 Èmi mọ̀ ́n, ṣe ẹni ó rán mi láti fi omi bamitiisi sọ fún mi , Ọkùnrin ìwọ ̀sọ̀kalẹ̀ ó lórí ni ẹni yóò fi ̀Mímọ́ bamitiisi.34 Èmi ti i, mo jẹ́rìí , èyí ni Ọmọ Ọlọ́run."

Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu àkọ́kọ́

35 ọjọ́ kejì, Johanu dúró pẹ̀méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 36 Nígbà ó Jesu ó ti ń kọjá lọ, ó , "ó ̀dọ́-àgùntàn Ọlọ́run!"

37 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn méjì náà gbọ́ ohun ó yìí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ í tọ Jesu lẹ́yìn. 38 Nígbà náà ni Jesu yípadà, ó i wọ́n ń tọ òun lẹ́yìn, ó béèrè , "ni ̀yin ń ?"

Wọ́n fún un , "Rabbi" (ìtumọ̀ èyí í ṣe Olùkọ́ni), "Níbo ni ìwọ ń gbé?"

39 Ó fún wọn , "ó, ̀yin yóò i."

Wọ́n , wọ́n ibi ó ń gbé, wọ́n ̀dọ̀ rẹ̀ gbogbo ọjọ́ náà. Ó jẹ́ ìwọ̀n wákàtí kẹwàá ọjọ́.

40 Anderu arákùnrin Simoni Peteru jẹ́ ̀kan nínú àwọn méjì ó gbọ́ ̀rọ̀ Johanu, ó tọ Jesu lẹ́yìn. 41 Ohun àkọ́kọ́ Anderu ṣe ni láti Simoni arákùnrin rẹ̀, ó fún un , "Àwa ti Messia" (ẹni ṣe Kristi). 42 Ó un sọ́dọ̀ Jesu.

Jesu ó, ó , "Ìwọ ni Simoni ọmọ Jona: Kefa ni a ó máa " (ìtumọ̀ èyí ṣe Peteru).

Jesu pe Filipi àti Natanaeli

43 ọjọ́ kejì Jesu ń fẹ́ jáde lọ Galili, ó Filipi, ó fún un , "Máa tọ̀ lẹ́yìn."

44 Filipi gẹ́gẹ́ i Anderu àti Peteru, jẹ́ ará ìlú Betisaida. 45 Filipi Natanaeli, ó fún un , "Àwa ti ẹni náà Mose kọ nípa rẹ̀ nínú òfin àti ẹni àwọn wòlíì ti kọ̀rẹ̀, Jesu ti Nasareti, ọmọ Josẹfu."

46 Natanaeli béèrè , "Nasareti? Ohun rere kan ha ti ibẹ̀ jáde?"

Filipi fún un , "ó."

47 Jesu Natanaeli ń bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó nípa rẹ̀ , "Èyí ni ọmọ Israẹli tòótọ́, nínú ẹni ̀tàn ."

48 Natanaeli béèrè , "Báwo ni ìwọ ti ṣe mọ̀ ?"

Jesu dáhùn , "Èmi nígbà ìwọ lábẹ́ igi ̀pọ̀tọ́ Filipi ́."

49 Nígbà náà ni Natanaeli sọ ́ gbangba , "Rabbi, ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run; Ìwọ ni ọba Israẹli."

50 Jesu fún un , "Ìwọ gbàgbọ́ nítorí mo fún mo lábẹ́ igi ̀pọ̀tọ́. Ìwọ ó ohun ó pọ̀ìwọ̀nyí lọ." 51 Nígbà náà ni ó fi kún un , "Èmi fún yín nítòótọ́, ̀yin yóò ̀run ṣí sílẹ̀, àwọn angẹli Ọlọ́run yóò máa gòkè, wọ́n ó máa sọ̀kalẹ̀ sórí Ọmọ Ènìyàn."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-