Pular para o conteúdo
Publicidade

Johanu 14

16 14.16: Jh 14.26; 15.26; 16.7; 1Jh 2.1.Nígbà náà èmi yóò béèrè lọ́wọ́ Baba. Òun yóò fún yín olùtùnú mìíràn. Olùtùnú náà yóò máa yín gbé títí láé. 17 Òun ni ̀òtítọ́. Ayé le gbà á. Nítorí ayé mọ̀ ́n, bẹ́̀ ni i . ̀yin mọ̀ ọn nítorí láti ìgbà ti pẹ̀. Òun náà ti pẹ̀yín. Ṣùgbọ́n ọjọ́ kan yóò wọ inú yín láti máa gbé ibẹ̀. 18 Èmi fi yín sílẹ̀ láìní Olùtùnú, ma dàbí ọmọ òbí. Rárá o! Mo tún ń tọ̀ yín bọ̀. 19 14.19: Jh 7.33.Nígbà díẹ̀ i, ayé yóò mi mọ́; ṣùgbọ́n ̀yin yóò mi, nítorí èmi láààyè, ̀yin yóò láààyè pẹ̀. 20 ọjọ́ náà ni ̀yin yóò mọ̀ , èmi nínú Baba mi, àti ̀yin nínú mi, àti èmi nínú yín. 21 Ẹni ó òfin mi, ó ń pa wọ́n mọ́, òun ni ẹni ó fẹ́ràn mi, ẹni ó fẹ́ràn mi, a ó fẹ́ràn rẹ̀ láti ̀dọ̀ Baba mi, èmi ó fẹ́ràn rẹ̀, èmi ó fi ara mi hàn fún un."

22 Judasi (í ṣe Judasi Iskariotu) fún un , "Olúwa, èéha ti ṣe ìwọ ó fi ara rẹ hàn fún àwa, yóò ṣe fún aráyé?"

23 14.23: 1Jh 2.24; If 21.3. Jesu dáhùn ó fún un , "ẹnìkan fẹ́ràn mi, yóò pa ̀rọ̀ mi mọ́. Baba mi yóò fẹ́ràn rẹ̀, àwa ó tọ̀ ́ , a ó ṣe ibùgbé wa pẹ̀rẹ̀. 24 Ẹni fẹ́ràn mi ni pa ̀rọ̀ mi mọ́. ̀rọ̀ ̀yin ń gbọ́ í ṣe ti èmi, ṣùgbọ́n ti Baba ó rán mi.

25 "Nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti sọ fún yín, nígbà mo ń yín gbé. 26 Ṣùgbọ́n Olùtùnú náà, ̀Mímọ́, ẹni Baba yóò rán orúkọ mi, òun ni yóò kọ́ yín ohun gbogbo, yóò rán yín létí ohun gbogbo mo ti sọ fún yín.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também