Pular para o conteúdo
Publicidade

João 16

7 16.7: Jh 14.16,26; 15.26.Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni èmi ń sọ fún yín; àǹfààní ni yóò jẹ́ fún yín èmi lọ, nítorí èmi lọ, Olùtùnú yóò tọ̀ yín ; ṣùgbọ́n mo lọ, èmi ó rán an yín. 8 Nígbà òun , yóò fi òye aráyé ti ̀ṣẹ̀, àti ti òdodo, àti ti ìdájọ́, 9 16.9: Jh 15.22.ti ̀ṣẹ̀, nítorí wọn gbà gbọ́; 10 16.10: Ap 3.14; 7.52; 1Pt 3.18.ti òdodo, nítorí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba, ̀yin mọ̀ . 11 16.11: Jh 12.31.ti ìdájọ́, nítorí a ti ṣe ìdájọ́ ọmọ-aládé ayé yìí.

Veja também