Publicidade

João 17

Jesu gbàdúrà fún ara rẹ̀

1 Nǹkan wọ̀nyí ni Jesu sọ, ó gbé ojú rẹ̀ sókè ̀run, ó ,

"Baba, wákàtí náà , yin ọmọ rẹ lógo, ọmọ rẹ ó yìn ́ lógo pẹ̀. 2 Gẹ́gẹ́ ìwọ ti fún un àṣẹ lórí ènìyàn gbogbo, ó fi ìyè àìnípẹ̀kun fún gbogbo àwọn ó fi fún un. 3 Ìyè àìnípẹ̀kun náà ni èyí, wọn ó mọ ìwọ nìkan Ọlọ́run òtítọ́, àti Jesu Kristi, ẹni ìwọ rán. 4 Èmi ti yìn ́ lógo ayé: èmi ti parí iṣẹ́ ìwọ fi fún mi láti ṣe. 5 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, Baba, ṣe lógo pẹ̀ara rẹ, ògo mo ti pẹ̀rẹ ayé ó .

Jesu gbàdúrà fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn

6 "Èmi ti fi orúkọ rẹ hàn fún àwọn ènìyàn ìwọ ti fún mi láti inú ayé , tìrẹ ni wọ́n ti jẹ́, ìwọ ti fi wọ́n fún mi; wọ́n ti pa ̀rọ̀ rẹ mọ́. 7 Nísinsin yìí, wọ́n mọ̀ ohunkóhun gbogbo ìwọ ti fi fún mi, láti ̀dọ̀ rẹ ni. 8 Nítorí ̀rọ̀ ìwọ fi fún mi, èmi ti fi fún wọn, wọ́n ti gbà á, wọ́n ti mọ̀ nítòótọ́ , lọ́dọ̀ rẹ ni mo ti jáde , wọ́n gbàgbọ́ ìwọ ni ó rán mi. 9 Èmi ń gbàdúrà fún wọn, èmi gbàdúrà fún aráyé, ṣùgbọ́n fún àwọn ìwọ ti fi fún mi; nítorí tìrẹ ni wọ́n í ṣe. 10 Tìrẹ à ni gbogbo ohun í ṣe tèmi, àti tèmi ni gbogbo ohun í ṣe tìrẹ, a ti ṣe lógo nínú wọn. 11 Èmi ayé mọ́, àwọn wọ̀nyí ń bẹ ayé, èmi ń bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ. Baba mímọ́, pa àwọn o ti fi fún mi mọ́, orúkọ rẹ, wọn ó jẹ́ ̀kan, àní gẹ́gẹ́ àwa. 12 Nígbà mo pẹ̀wọn ayé, mo pa wọ́n mọ́ orúkọ rẹ; àwọn ìwọ fi fún mi, ni mo ti pamọ́, ẹnìkan nínú wọn sọnù ṣe ọmọ ègbé; ìwé mímọ́ ó le ṣẹ.

13 "Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi ń bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ, nǹkan wọ̀nyí ni mo ń sọ ayé, wọn ó ayọ̀ mi kíkún nínú àwọn tìkára wọn. 14 Èmi ti fi ̀rọ̀ rẹ fún wọn; ayé ti kórìíra wọn, nítorí wọn í ṣe ti ayé, gẹ́gẹ́ èmi í ti í ṣe ti ayé. 15 Èmi gbàdúrà , ìwọ ó wọn kúrò ayé, ṣùgbọ́n ìwọ ó pa wọ́n mọ́ kúrò nínú ibi. 16 Wọn í ṣe ti ayé, gẹ́gẹ́ èmi í ti í ṣe ti ayé. 17 Sọ wọ́n di mímọ́ nínú òtítọ́, òtítọ́ ni ̀rọ̀ rẹ. 18 Gẹ́gẹ́ ìwọ ti rán mi ayé, bẹ́̀ ni èmi rán wọn ayé pẹ̀. 19 Èmi ya ara mi mímọ́ nítorí wọn, a sọ àwọn tìkára wọn pẹ̀di mímọ́ nínú òtítọ́.

Jesu gbàdúrà fún gbogbo onígbàgbọ́

20 "í ṣe kìkì àwọn wọ̀nyí ni mo ń gbàdúrà fún, ṣùgbọ́n fún àwọn pẹ̀yóò gbà gbọ́ nípa ̀rọ̀ wọn. 21 gbogbo wọn ó jẹ́ ̀kan; gẹ́gẹ́ ìwọ, Baba, ti jẹ́ nínú mi, àti èmi nínú rẹ, àwọn pẹ̀ó jẹ́ ̀kan nínú wa, ayé ó gbàgbọ́ , ìwọ ni ó rán mi. 22 Ògo ìwọ ti fi fún mi ni èmi ti fi fún wọn; wọn ó jẹ́ ̀kan, gẹ́gẹ́ àwa ti jẹ́ ̀kan. 23 Èmi nínú wọn, àti ìwọ nínú mi, a ṣe wọ́n ̀kan; ayé ó mọ̀ , ìwọ ni ó rán mi, àti ìwọ fẹ́ràn wọn gẹ́gẹ́ ìwọ ti fẹ́ràn mi.

24 "Baba, èmi fẹ́ àwọn ìwọ fi fún mi, ó lọ́dọ̀ mi, níbi èmi gbé ; wọn máa wo ògo mi, ìwọ ti fi fún mi, nítorí ìwọ à fẹ́ràn mi síwájú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.

25 "Baba olódodo, ayé mọ̀ ́n; ṣùgbọ́n èmi mọ̀ ́n, àwọn wọ̀nyí mọ̀ ìwọ ni ó rán mi. 26 Mo ti sọ orúkọ rẹ di mọ̀ fún wọn, èmi ó sọ ́ di mọ̀: ìfẹ́ ìwọ fẹ́ràn mi, máa nínú wọn, àti èmi nínú wọn."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-