31 Láàrín èyí, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń rọ̀ ọ́ wí pé, "Rabbi, jẹun."
32 4.32: Mt 4.4. Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, "Èmi ní oúnjẹ láti jẹ, tí ẹ̀yin kò mọ̀."
33 Nítorí náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bi ara wọn lérè wí pé, "Ẹnìkan mú oúnjẹ fún un wá láti jẹ bí?"
34 4.34: Jh 5.30; 6.38; 17.4. Jesu wí fún wọn pé, "Oúnjẹ mi ni láti ṣe ìfẹ́ ẹni tí ó rán mi, àti láti parí iṣẹ́ rẹ̀.