Pular para o conteúdo
Publicidade

João 9

Jesu la ojú ẹni a afọ́

1 ó ti ń kọjá lọ, ó ọkùnrin kan ó fọ́láti ìgbà ìbí rẹ̀ . 2 9.2: Lk 13.2; Ap 28.4; El 18.20; El 20.5.Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bi í léèrè, , "Rabbi, ta ó dẹ́ṣẹ̀, ọkùnrin yìí tàbí àwọn òbí rẹ̀, a fi i afọ́?"

3 9.3: Jh 11.4. Jesu dáhùn , "í ṣe nítorí ọkùnrin yìí dẹ́ṣẹ̀, tàbí àwọn òbí rẹ̀: ṣùgbọ́n a ba à fi iṣẹ́ Ọlọ́run hàn lára rẹ̀. 4 9.4: Jh 11.9; 12.35.Èmi láti ṣe iṣẹ́ ẹni ó rán mi, níwọ̀n ìgbà ó ti jẹ́ ̀sán, òru ń bọ̀ nígbà ẹnìkan yóò ṣe iṣẹ́. 5 9.5: Jh 1.4; 8.12; 12.46.Níwọ́n ìgbà mo láààyè, èmi ni ìmọ́lẹ̀ ayé."

6 9.6: Mk 7.33; 8.23. Nígbà ó ti bẹ́̀ tan, ó tutọ́ sílẹ̀, ó fi itọ́ náà ṣe amọ̀, ó fi amọ̀ náà ra ojú afọ́náà. 7 9.7: Lk 13.4.Ó fún un , "Lọ wẹ̀ nínú adágún Siloamu!" (Ìtumọ̀ ̀rọ̀ yìí ni "rán"). Nítorí náà ó gba ̀rẹ̀ lọ, ó wẹ̀, ó , ó ń ríran.

Veja também