Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 1

Orin Maria

46 Maria dáhùn, ó :

"Ọkàn mi yin Olúwa lógo.

47 ̀mi yọ̀ Ọlọ́run Olùgbàlà mi.

48 Nítorí ó síjú wo ìwà ìrẹ̀lẹ̀

ọmọbìnrin ̀dọ̀ rẹ̀. ó,

láti ìsinsin yìí lọ gbogbo ìran ènìyàn ni yóò máa alábùkún fún.

49 Nítorí ẹni ó agbára ti ṣe ohun ó tóbi fún mi;

Mímọ́ ni orúkọ rẹ̀.

50 Àánú rẹ̀ ń bẹ fún àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

láti ìrandíran.

51 Ó ti fi agbára hàn apá rẹ̀;

o ti àwọn onígbèéraga ìrònú ọkàn wọn.

52 Ó ti àwọn alágbára kúrò lórí ìtẹ́ wọn,

o gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ lékè.

53 Ó ti fi ohun ó dára kún àwọn ebi ń pa

ó rán àwọn ọlọ́rọ̀ padà òfo.

54 Ó ti ran Israẹli ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́,

ìrántí àánú rẹ̀;

55 1.55: Mt 7.20; Gẹ 17.7; 18.18; 22.17. Abrahamu àti àwọn ìran rẹ̀ láéláé, baba wa,

àti ó ti sọ fún àwọn baba wa."

Veja também