Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 1

59 1.59: Le 12.3; Gẹ 17.12. Ó ṣe, ọjọ́ kẹjọ wọ́n láti kọ ọmọ náà nílà; wọ́n fẹ́ sọ orúkọ rẹ̀ Sekariah, gẹ́gẹ́ orúkọ baba rẹ̀. 60 Ìyá rẹ̀ dáhùn, ó , "Bẹ́̀ kọ́! Johanu ni a ó é."

61 Wọ́n fún un , "̀kan nínú àwọn ará rẹ̀ à ń orúkọ yìí."

62 Wọ́n ṣe àpẹẹrẹ baba rẹ̀, ó ti ń fẹ́ a é. 63 Ó béèrè fún wàláà, ó kọ , "Johanu ni orúkọ rẹ̀." Ẹnu ya gbogbo wọn. 64 Ẹnu rẹ̀ ṣí lọ́gán, okùn ahọ́n rẹ̀ , ó sọ̀rọ̀, ó ń yin Ọlọ́run.

Veja também