Publicidade

Lucas 12

Àwọn ìkìlọ̀ àti ̀rọ̀ ìyànjú

1 Ó ṣe, nígbà àìníye ìjọ ènìyàn péjọpọ̀, bẹ́̀ wọn ń tẹ ara wọn mọ́lẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sísọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "máa ṣọ́ra yín nítorí ìwúkàrà àwọn Farisi í ṣe àgàbàgebè. 2 ohun a , a yóò fihàn; tàbí ó pamọ́, a yóò mọ̀. 3 Nítorí náà ohunkóhun ̀yin sọ òkùnkùn, gbangba ni a ó ti gbọ́ ; àti ohun ̀yin sọ etí iyàrá, lórí òrùlé ni a ó ti kéde rẹ̀.

4 "Èmi fún yín ̀yin ̀rẹ́ mi, ṣe bẹ̀àwọn ó ń pa ara ènìyàn , lẹ́yìn èyí, wọn èyí wọ́n ṣe mọ́. 5 Ṣùgbọ́n èmi ó sọ ẹni ̀yin ó bẹ̀fún yín: bẹ̀ẹni ó lágbára lẹ́yìn ó pànìyàn tan, láti wọ́ ni lọ ̀run àpáàdì. Lóòótọ́ ni mo fún yín òun ni bẹ̀. 6 Ológoṣẹ́ márùn-ún à ni a ń owó idẹ wẹ́wẹ́ méjì? A gbàgbé ̀kan nínú wọn níwájú Ọlọ́run? 7 Ṣùgbọ́n gbogbo irun orí yín ni a ṣánṣán. Nítorí náà ṣe bẹ̀, ̀yin iye lórí ju ológoṣẹ́ púpọ̀ lọ.

8 "Mo fún yín pẹ̀, Ẹnikẹ́ni ó jẹ́wọ́ mi níwájú àwọn ènìyàn. Ọmọ Ènìyàn yóò jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run. 9 Ṣùgbọ́n ẹni ó sẹ́ mi níwájú ènìyàn, a ó sẹ́ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run. 10 Àti ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀-òdì Ọmọ Ènìyàn, a ó dárí rẹ̀ í; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀-òdì ̀Mímọ́, a yóò dárí rẹ̀ í.

11 "Nígbà wọ́n yin Sinagọgu, àti síwájú àwọn olórí, àti àwọn aláṣẹ, ṣe ṣàníyàn , báwo tàbí ohun kín ni ̀yin yóò fèsì rẹ̀ tàbí kín ni ̀yin ó . 12 Nítorí ̀Mímọ́ yóò kọ́ yín wákàtí kan náà ohun ó yẹ sọ."

Ìtàn òmùgọ̀ ọlọ́rọ̀

13 ̀kan nínú àwùjọ fún un , "Olùkọ́, sọ fún arákùnrin mi ó pín mi ogún."

14 Ó fún un , "Ọkùnrin yìí, ta ni ó fi jẹ onídàájọ́ tàbí olùpíngún fún yín?" 15 Ó fún wọn , "Kíyèsára o máa ṣọ́ra nítorí ojúkòkòrò: nítorí ìgbésí ayé ènìyàn dúró ̀pọ̀ ohun ó ."

16 Ó pa òwe kan fún wọn , "Ilẹ̀ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ so ̀pọ̀lọpọ̀ èso. 17 Ó nínú ara rẹ̀ , Èmi ó ti ṣe, nítorí èmi ibi èmi ó gbé èso mi jọ .

18 "Ó , Èyí ni èmi ó ṣe: èmi ó àká mi palẹ̀, èmi ó kọ́ èyí ó tóbi; níbẹ̀ ni èmi ó gbé to gbogbo èso àti ọrọ̀ mi jọ . 19 Èmi ó fún ọkàn mi , ọkàn, ìwọ ọrọ̀ púpọ̀ a jọ fún ̀pọ̀ ọdún; sinmi, máa jẹ, máa mu, máa yọ̀.’

20 "Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fún un , Ìwọ aṣiwèrè, lóru yìí ni a ó béèrè ọkàn rẹ lọ́wọ́ rẹ; ǹjẹ́ ti ta ni nǹkan wọ̀nyí yóò ha ṣe, ìwọ ti pèsè sílẹ̀?’

21 "Bẹ́̀ ni ẹni ó to ìṣúra jọ fún ara rẹ̀, ọrọ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run."

ṣe ṣe àníyàn

22 Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Nítorí náà mo fún yín , ṣe ṣe àníyàn nítorí ̀yín , kín ni ̀yin yóò jẹ tàbí nípa ara yin pe kín ni ẹyin o fi bora. 23 ̀à ju oúnjẹ lọ, ara ju aṣọ lọ. 24 kíyèsi àwọn ẹyẹ ìwò: wọn í fúnrúgbìn, bẹ́̀ ni wọn í kórè: wọn àká, bẹ́̀ ni wọn abà, Ọlọ́run à ń bọ́ wọn: mélòó mélòó ni ̀yin fi sàn ju ẹyẹ lọ! 25 Ta ni nínú yín nípa àníyàn ṣíṣe ó fi ìgbọ̀nwọ́ kan kún ọjọ́ ayé rẹ̀? 26 Ǹjẹ́ ̀yin ti ṣe èyí ó kéré eléyìí, èéṣe ̀yin fi ń ṣàníyàn nítorí ìyókù?

27 "kíyèsi àwọn lílì wọ́n ti ń dàgbà; wọn í ṣiṣẹ́, wọn í rànwú; ṣùgbọ́n èmi fún yín, a ṣe Solomoni pàápàá lọ́ṣọ̀́ gbogbo ògo rẹ̀ ̀kan nínú ìwọ̀nyí. 28 Ǹjẹ́ Ọlọ́run wọ koríko igbó aṣọ bẹ́̀ èyí ó lónìí, a gbá a sínú iná lọ́la: mélòó mélòó ni yóò wọ̀ yín láṣọ, ̀yin onígbàgbọ́ kékeré. 29 ṣe ohun ó jẹ, tàbí ohun ó mu, ṣe ṣe àníyàn nínú ọkàn. 30 Nítorí gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè ayé ń kiri. Baba yín mọ̀ , ̀yin ń fẹ́ nǹkan wọ̀nyí. 31 Ṣùgbọ́n máa ìjọba Ọlọ́run, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni a ó fi kún un fún yín.

32 "bẹ̀, agbo kékeré, nítorí dídùn inú Baba yín ni láti fi ìjọba fún yín. 33 ta ohun ̀yin , tọrẹ àánú pèsè àpò fún ara yín, í gbó, ìṣúra ̀run í tán, ibi olè súnmọ́, àti ibi kòkòrò í á jẹ́. 34 Nítorí ibi ìṣúra yín gbé , níbẹ̀ ni ọkàn yín yóò gbé pẹ̀.

máa ṣọ́

35 "di àmùrè yín, fìtílà yín máa . 36 ̀yin tìkára yín dàbí ẹni ń retí olúwa wọn, nígbà òun ó padà ti ibi ìgbéyàwó , nígbà ó , ó kànkùn, wọn ṣí i sílẹ̀ fún un lọ́gán. 37 Ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ náà nígbà olúwa náà yóò wọn wọn ń ṣọ́; lóòótọ́ ni mo fún yín, yóò di ara rẹ̀ àmùrè yóò wọn jókòó láti jẹun, yóò jáde láti ṣe ìránṣẹ́ fún wọn. 38 olúwa wọn nígbà ìṣọ́ kejì, tàbí ó nígbà ìṣọ́ kẹta, ó wọn bẹ́̀, ìbùkún ni fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ náà. 39 Ṣùgbọ́n mọ èyí , baálé ilé ìbá mọ wákàtí olè yóò , òun ìbá máa ṣọ́, jẹ́ a wọ inú ilé òun. 40 Nítorí náà, ̀yin múra pẹ̀, nítorí Ọmọ Ènìyàn ń bọ̀ wákàtí ̀yin nírètí."

41 Peteru , "Olúwa, ìwọ pa òwe yìí fún wa, tàbí fún gbogbo ènìyàn?"

42 Olúwa dáhùn , "Ta ni olóòtítọ́ àti ọlọ́gbọ́n ìríjú náà, olúwa rẹ̀ fi jẹ olórí agbo ilé rẹ̀, láti máa fi ìwọ̀n oúnjẹ wọ́n fún wọn àkókò? 43 Ìbùkún ni fún ọmọ ̀dọ̀ náà, nígbà olúwa rẹ̀ , yóò a ó máa ṣe bẹ́̀. 44 Lóòótọ́ ni mo fún yín yóò fi jẹ olórí ohun gbogbo ó . 45 Ṣùgbọ́n ọmọ ̀dọ̀ náà ọkàn rẹ̀, , Olúwa mi fi ìgbà bíbọ̀ rẹ̀ falẹ̀!’ ó bẹ̀rẹ̀ í lu àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin ó bẹ̀rẹ̀ í jẹ àti mu àmupara: 46 Olúwa ọmọ ̀dọ̀ náà yóò ọjọ́ retí rẹ̀, àti wákàtí dábàá, yóò jẹ ́ gidigidi, yóò yan ipò rẹ̀ pẹ̀àwọn aláìgbàgbọ́.

47 "Àti ọmọ ̀dọ̀ náà, ó mọ ìfẹ́ olúwa rẹ̀, múra sílẹ̀, ṣe gẹ́gẹ́ ìfẹ́ rẹ̀, òun ni a ó púpọ̀. 48 Ṣùgbọ́n èyí mọ̀, ó ṣe ohun ó yẹ lílù, òun ni a ó níwọ̀n. Nítorí ẹnikẹ́ni a fún púpọ̀, lọ́dọ̀ rẹ̀ ni a ó gbé béèrè púpọ̀: lọ́dọ̀ ẹni a gbé fi púpọ̀ , lọ́dọ̀ rẹ ni a ó gbé béèrè i.

Àlàáfíà kọ́ ṣùgbọ́n ìyapa

49 "Iná ni èmi láti sọ ayé; kín ni èmi ń fẹ́ ṣe iná náà ti jo! 50 Ṣùgbọ́n èmi bamitiisi kan a ó fi bamitiisi mi; ara ti ń ni títí yóò fi parí! 51 ̀yin ṣe àlàáfíà ni èmi fi ayé? Mo fún yín, bẹ́̀ kọ́; ṣùgbọ́n ṣe ìyapa. 52 Nítorí láti ìsinsin yìí lọ, ènìyàn márùn-ún yóò ilé kan náà a ó ipa, mẹ́ta méjì, àti méjì mẹ́ta. 53 A ó ya baba nípa ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti ọmọ ọkùnrin baba; ìyá ọmọbìnrin, àti ọmọbìnrin ìyá rẹ̀, ìyá ọkọ ìyàwó ọmọ, àti ìyàwó ọmọ ìyá ọkọ rẹ̀."

Ògbufọ̀ àwọn àkókò

54 Ó fún ìjọ ènìyàn pẹ̀, "Nígbà ̀yin àwọsánmọ̀ ó ṣú ìhà ìwọ̀-oòrùn, lọ́gán ni ̀yin yóò sọ , ̀wààrà òjò ń bọ̀,’ a bẹ́̀. 55 Nígbà afẹ́fẹ́ gúúsù ń fẹ́, ̀yin á , Oòrùn yóò ,yóò ṣe bẹ́̀. 56 ̀yin àgàbàgebè! ̀yin le mòye ojú ̀run àti ti ayé. Èéha ti ṣe ̀yin mọ àkókò yìí?

57 "Èéha ti ṣe ̀yin tìkára yín fi ro ohun ó tọ́? 58 Nígbà ìwọ ̀rẹ lọ sọ́dọ̀ onídàájọ́, i o a parí ̀rọ̀ ̀ó ba à ́ fún adájọ́, adájọ́ a fi ́ ̀ṣọ́ lọ́wọ́, òun a ́ sínú túbú. 59 èmi fún , ìwọ yóò jáde kúrò níbẹ̀, títí ìwọ ó fi san ẹyọ owó kan ó !"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-