Publicidade

Lucas 19

Sakeu agbowó òde

1 Jesu wọ Jeriko lọ, ó ń kọjá láàrín rẹ̀. 2 kíyèsi i, ọkùnrin kan a ń Sakeu, ó jẹ́ olórí agbowó òde kan, ó jẹ́ ọlọ́rọ̀. 3 Ó ń fẹ́ láti ẹni Jesu jẹ́: i, nítorí ̀pọ̀ ènìyàn, àti nítorí òun jẹ́ ènìyàn kúkúrú. 4 Ó súré síwájú, ó gun orí igi sikamore kan, ó i: nítorí yóò kọjá lọ níhà ibẹ̀.

5 Nígbà Jesu ibẹ̀, ó gbé ojú sókè, ó i, ó fún un , "Sakeu! Yára, o sọ̀kalẹ̀; nítorí èmi yóò wọ ilé rẹ lónìí." 6 Ó yára, ó sọ̀kalẹ̀, ó fi ayọ̀ gbà á.

7 Nígbà wọ́n i, gbogbo wọn ń kùn, , "Ó lọ ọkùnrin ẹlẹ́ṣẹ̀ náà àlejò."

8 Sakeu dìde, ó fún Olúwa , "ó, Olúwa, ààbọ̀ ohun ìní mi ni mo fi fún tálákà; mo fi èké gba ohun kan lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, èmi san án padà ìlọ́po mẹ́rin!"

9 Jesu fún un , "Lónìí ni ìgbàlà wọ ilé yìí, níwọ̀n òun pẹ̀ti jẹ́ ọmọ Abrahamu. 10 Nítorí Ọmọ Ènìyàn láti àwọn ó kiri, àti láti gbà wọ́n ."

Òwe mina mẹ́wàá

11 Nígbà wọ́n ń gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ó tẹ̀síwájú láti pa òwe kan, nítorí ó súnmọ́ Jerusalẹmu, àti nítorí wọn ń , ìjọba Ọlọ́run yóò farahàn nísinsin yìí. 12 Ó , "Ọkùnrin ọlọ́kan lọ ìlú òkèrè láti gba ìjọba ó padà. 13 Ó pe àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ mẹ́wàá, ó fi owó mina mẹ́wàá fún wọn, ó fún wọn , máa ṣòwò títí èmi ó fi !

14 "Ṣùgbọ́n àwọn ará ìlù rẹ̀ kórìíra rẹ̀, wọ́n rán ikọ̀ tẹ̀e, , Àwa fẹ́ ọkùnrin yìí jẹ ọba lórí wa.

15 "Nígbà ó gba ìjọba tan, ó padà , ó pàṣẹ , a pe àwọn ọmọ ̀dọ̀ wọ̀nyí òun ti fi owó fún sọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí ó le mọ iye èrè olúkúlùkù ti jẹ nínú iṣẹ́ òwò wọn.

16 "Èyí èkínní , ó , Olúwa, owó mina rẹ jèrè owó mina mẹ́wàá i.

17 "Olúwa rẹ̀ fún un , O ṣeun, ìwọ ọmọ ̀dọ̀ rere! Nítorí ìwọ ṣe olóòtítọ́ ohun kínkínní, gba àṣẹ lórí ìlú mẹ́wàá.

18 "Èyí èkejì , ó , Olúwa, owó mina rẹ jèrè owó mina márùn.

19 "Olúwa rẹ fún un pẹ̀, Ìwọ pẹ̀joyè ìlú márùn-ún!

20 "Òmíràn , ó , Olúwa, ó owó mina rẹ ń bẹ lọ́wọ́ mi ni mo sínú aṣọ pélébé kan; 21 nítorí mo bẹ̀rẹ, àti nítorí ìwọ ṣe òǹrorò ènìyàn, ìwọ a máa èyí ìwọ fi lélẹ̀, ìwọ a máa èyí ìwọ gbìn!

22 "Olúwa rẹ fún un , ẹnu ara rẹ náà ni èmi ó ṣe ìdájọ́ rẹ, ìwọ ọmọ ̀dọ̀ búburú, ìwọ mọ̀ òǹrorò ènìyàn ni , , èmi a máa èyí èmi fi lélẹ̀ èmi a máa èyí èmi gbìn. 23 Èéha ti ṣe ìwọ fi owó mi pamọ́ ilé ìfowópamọ́, nígbà mo , èmi ìbá ti béèrè rẹ̀ pẹ̀èlé?

24 "Ó fún àwọn ó dúró létí ibẹ̀ , gba owó mina náà lọ́wọ́ rẹ̀, fi í fún ẹni ó owó mina mẹ́wàá.

25 "Wọ́n fún un , Olúwa, ó owó mina mẹ́wàá.

26 "Mo fún yín , Ẹnikẹ́ni ó , ni a ó fi fún, àti lọ́dọ̀ ẹni èyí ó pàápàá a ó gbà á lọ́wọ́ rẹ̀. 27 Ṣùgbọ́n àwọn ̀mi wọ̀nyí, fẹ́ èmi jẹ ọba lórí wọn wọn ìhín yìí, pa wọ́n níwájú mi!’ "

Ó wọ ilé pẹ̀kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́

28 Nígbà ó ti nǹkan wọ̀nyí tan, ó lọ síwájú, ó ń gòkè lọ Jerusalẹmu. 29 Ó ṣe, nígbà ó súnmọ́ Betfage àti Betani òkè a ń òkè olifi, ó rán àwọn méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 30 , "lọ ìletò ó kọjú yín; nígbà ̀yin wọ̀ ́ lọ, ̀yin ó ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan a so, ẹnikẹ́ni gùn , u, á . 31 ẹnikẹ́ni bi yín , Èéṣe ̀yin fi ń u?̀yin báyìí , Olúwa ń fẹ́ ó.’ "

32 Àwọn a rán ̀wọn pọ̀n, wọ́n a gẹ́gẹ́ ó ti fún wọn. 33 wọ́n ti ń ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, àwọn Olúwa rẹ̀ bi wọ́n , "Èéṣe ̀yin fi ń tu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà?"

34 Wọ́n , "Olúwa fẹ́ ó."

35 Wọ́n á tọ Jesu , wọ́n tẹ́ aṣọ ̀yìn ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, wọ́n gbé Jesu á. 36 ó ti ń lọ wọ́n tẹ́ aṣọ wọn ̀.

37 ó ti súnmọ́ etí ibẹ̀ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè olifi, gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bẹ̀rẹ̀ í yọ̀, wọ́n fi ohùn rara yin Ọlọ́run, nítorí iṣẹ́ ńlá gbogbo wọ́n ti ,

38 , "Olùbùkún ni ọba ó ń bọ̀ orúkọ Olúwa!"

"Àlàáfíà ̀run, àti ògo ni òkè ̀run!"

39 Àwọn kan nínú àwọn Farisi nínú àwùjọ náà fún un , "Olùkọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ ."

40 Ó wọn lóhùn, ó fún wọn , "Mo fún yín, àwọn wọ̀nyí pa ẹnu wọn mọ́, àwọn òkúta yóò kígbe sókè."

41 Nígbà ó súnmọ́ etílé, ó síjú wo ìlú náà, ó sọkún i lórí, 42 Ó ń , "Ìbá ṣe ìwọ mọ̀, lónìí yìí, àní ìwọ, ohun í ṣe àlàáfíà rẹ! Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n pamọ́ kúrò lójú rẹ. 43 Nítorí ọjọ́ ń bọ̀ fún , àwọn ̀rẹ yóò mọ odi bèbè , àní wọn yóò , wọn ó mọ́ níhà gbogbo. 44 Wọn ó palẹ̀ ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ pẹ̀rẹ; wọn yóò fi òkúta kan sílẹ̀ lórí ara wọn; nítorí ìwọ mọ ọjọ́ ìbẹ̀rẹ."

Jesu nínú tẹmpili

45 Ó wọ inú tẹmpili lọ, ó bẹ̀rẹ̀ àwọn ń nínú rẹ̀ sóde; 46 Ó fún wọn , "A ti kọ̀rẹ̀ , Ilé mi yóò jẹ́ ilé àdúrà?Ṣùgbọ́n ̀yin ti sọ ́ di ihò àwọn ọlọ́ṣà."

47 Ó ń kọ́ni lójoojúmọ́ tẹmpili, ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀, àti àwọn olórí àwọn ènìyàn ń ̀láti pa á. 48 Wọn nǹkan kan wọn ìbá ṣe; nítorí gbogbo ènìyàn ṣù mọ́ ọn láti gbọ́rọ̀ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-