19 22.19: Mt 26.26; Mk 14.22; 1Kọ 10.16; 11.23-26; Lk 9.16. Ó sì mú àkàrà, nígbà tí ó sì ti dúpẹ́ ó bù ú, ó sì fi fún wọn, ó wí pé, "Èyí ni ara mí tí a fi fún yín, ẹ máa ṣe èyí ní ìrántí mi."
20 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ lẹ́yìn oúnjẹ alẹ́, ó sì mú ago wáìnì, ó wí pé, "Ago yìí ni májẹ̀mú tuntun nínú ẹ̀jẹ̀ mi, tí a ta sílẹ̀ fún yín.