Publicidade

Lucas 3

Johanu onítẹ̀bọmi tún ọnà náà ṣe

1 ọdún kẹ́̀dógún ìjọba Tiberiu Kesari, nígbà Pọntiu Pilatu jẹ́ baálẹ̀ Judea, Herodu jẹ́ tetrarki Galili, Filipi arákùnrin rẹ̀ jẹ́ tetrarki Iturea àti ti Trakoniti, Lisania jẹ́ tetrarki Abilene, 2 Annasi òun Kaiafa ń ṣe olórí àwọn àlùfáà, nígbà náà ni ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Johanu ọmọ Sekariah ijù. 3 Ó gbogbo ilẹ̀ aginjù Jordani, ó ń wàásù ìtẹ̀bọmi ìrònúpìwàdà fún ìmúkúrò ̀ṣẹ̀, 4 a ti kọ ́ nínú ìwé ̀rọ̀ wòlíì Isaiah ,

"Ohùn ẹni ń kígbe ijù,

tún ̀Olúwa ṣe,

ipa ̀rẹ̀ tọ́.

5 Gbogbo ̀gbun ni a yóò kún,

gbogbo òkè ńlá àti òkè kékeré ni a ó tẹ́ pẹẹrẹ.

Wíwọ́ ni a ó ṣe títọ́,

àti ̀gbọ́ngungbọ̀ngun ni a o sọ di dídán.

6 Gbogbo ènìyàn ni yóò ìgbàlà Ọlọ́run.’ "

7 Nígbà náà ni ó fún ̀pọ̀ àwọn ènìyàn ó láti ṣe ìtẹ̀bọmi lọ́dọ̀ rẹ̀ , "̀yin ìran paramọ́lẹ̀, ta ni ó kìlọ̀ fún un yín láti kúrò nínú ìbínú ń bọ̀? 8 Nítorí náà ̀yin ó so èso ó yẹ fún ìrònúpìwàdà, ṣe í nínú ara yín , Àwa Abrahamu baba.èmi ó fún un yín, Ọlọ́run gbé ọmọ dìde fún Abrahamu nínú òkúta wọ̀nyí. 9 Àti nísinsin yìí pẹ̀, a fi àáké gbòǹgbò igi náà, gbogbo igi so èso rere, a óò ge lulẹ̀, a wọ sínú iná."

10 Àwọn ènìyàn ń bi í , "ni àwa ó ṣe?"

11 Ó dáhùn ó fún wọn , "Ẹni ó ̀méjì, ó fi ̀kan fún ẹni ; ẹni ó oúnjẹ, ó ṣe bẹ́̀ pẹ̀."

12 Àwọn agbowó òde tọ̀ ́ láti ṣe ìtẹ̀bọmi lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n bi í , "Olùkọ́, ni àwa ó ha ṣe?"

13 Ó fún wọn , "ṣe fi agbára gbà a ti rán yín lọ mọ́."

14 Àwọn ọmọ-ogun béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ , "Àti àwa, ni àwa ó ṣe?"

Ó fún wọn , "ṣe hùwà ipá ẹnikẹ́ni, ṣe ka ̀sùn èké ẹnikẹ́ni; òwò ̀yín yín."

15 àwọn ènìyàn ti ń retí, gbogbo wọn ń nínú ara wọn nítorí Johanu, òun ni Kristi tàbí òun kọ́; 16 Johanu dáhùn ó fún gbogbo wọn , "Lóòótọ́ ni èmi ń fi omi bamitiisi yín, ṣùgbọ́n ẹni ó lágbára lọ ń bọ̀, okùn bàtà ẹsẹ̀ ẹni èmi , Òun ni yóò fi ̀Mímọ́ àti iná bamitiisi yín. 17 Ẹni àtẹ rẹ̀ ń bẹ ọwọ́ rẹ̀, láti gbá ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ mọ́ , ó alikama rẹ̀ sínú àká; ṣùgbọ́n ìyàngbò ni yóò fi iná àjóòkú sun." 18 Johanu lo oríṣìíríṣìí ̀rọ̀ púpọ̀ láti gba àwọn ènìyàn níyànjú àti láti wàásù ìyìnrere fún wọn.

19 Ṣùgbọ́n nígbà ti Johanu Herodu tetrarki, ó nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀, àti nítorí ohun búburú gbogbo Herodu ṣe, 20 Ó fi èyí parí gbogbo rẹ̀ nígbà ó fi Johanu sínú túbú.

Ìtẹ̀bọmi àti ìtàn ìdílé Jesu

21 Nígbà a ṣe ìtẹ̀bọmi àwọn ènìyàn gbogbo tán, ó ṣe, a bamitiisi Jesu pẹ̀, ó ti ń gbàdúrà, ̀run ṣí sílẹ̀, 22 ̀Mímọ́ sọ̀kalẹ̀ orí rẹ̀ àwọ̀ àdàbà, ohùn kan ti ̀run , ó , "Ìwọ ni àyànfẹ́ ọmọ mi; ẹni inú mi dùn gidigidi."

23 Jesu tìkára rẹ̀ ń ẹni ọgbọ̀n ọdún, nígbà ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ ó jẹ́ (a ti fi ) ọmọ Josẹfu,

í ṣe ọmọ Eli, 24 í ṣe ọmọ Mattati,

í ṣe ọmọ Lefi, í ṣe ọmọ Meliki,

í ṣe ọmọ Janai, í ṣe ọmọ Josẹfu,

25 í ṣe ọmọ Mattatia, í ṣe ọmọ Amosi,

í ṣe ọmọ Naumu, í ṣe ọmọ Esili,

í ṣe ọmọ Nagai, 26 í ṣe ọmọ Maati,

í ṣe ọmọ Mattatia, í ṣe ọmọ Ṣimei,

í ṣe ọmọ Josẹfu, í ṣe ọmọ Joda,

27 í ṣe ọmọ Joana, í ṣe ọmọ Resa,

í ṣe ọmọ Serubbabeli, í ṣe ọmọ Ṣealitieli,

í ṣe ọmọ Neri, 28 í ṣe ọmọ Meliki,

í ṣe ọmọ Adi, í ṣe ọmọ Kosamu,

í ṣe ọmọ Elmadamu, í ṣe ọmọ Eri,

29 í ṣe ọmọ Joṣua, í ṣe ọmọ Elieseri,

í ṣe ọmọ Jorimu, í ṣe Mattati,

í ṣe ọmọ Lefi, 30 í ṣe ọmọ Simeoni,

í ṣe ọmọ Juda, í ṣe ọmọ Josẹfu,

í ṣe ọmọ Jonamu, í ṣe ọmọ Eliakimu,

31 í ṣe ọmọ Melea, í ṣe ọmọ Menna,

í ṣe ọmọ Mattata, í ṣe ọmọ Natani,

í ṣe ọmọ Dafidi, 32 í ṣe ọmọ Jese,

í ṣe ọmọ Obedi, í ṣe ọmọ Boasi,

í ṣe ọmọ Salmoni, í ṣe ọmọ Nahiṣoni,

33 í ṣe ọmọ Amminadabu, í ṣe ọmọ Ramu,

í ṣe ọmọ Hesroni, í ṣe ọmọ Peresi,

í ṣe ọmọ Juda. 34 í ṣe ọmọ Jakọbu,

í ṣe ọmọ Isaaki, í ṣe ọmọ Abrahamu,

í ṣe ọmọ Tẹra, í ṣe ọmọ Nahori,

35 í ṣe ọmọ Serugu, í ṣe ọmọ Reu,

í ṣe ọmọ Pelegi, í ṣe ọmọ Eberi,

í ṣe ọmọ Ṣela. 36 í ṣe ọmọ Kainani,

í ṣe ọmọ Arfaksadi, í ṣe ọmọ Ṣemu,

í ṣe ọmọ Noa, í ṣe ọmọ Lameki,

37 í ṣe ọmọ Metusela, í ṣe ọmọ Enoku,

í ṣe ọmọ Jaredi, í ṣe ọmọ Mahalaleli,

í ṣe ọmọ Kainani. 38 í ṣe ọmọ Enosi,

í ṣe ọmọ Seti, í ṣe ọmọ Adamu,

í ṣe ọmọ Ọlọ́run.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-