Pular para o conteúdo
Publicidade

Lucas 6

6 6.6-11: Mt 12.9-14; Mk 3.1-6. ọjọ́ ìsinmi mìíràn, ó wọ inú Sinagọgu lọ, ó ń kọ́ni, ọkùnrin kan ń bẹ níbẹ̀ ọwọ́ ̀tún rẹ̀ rọ. 7 Àwọn akọ̀àti àwọn Farisi ń ṣọ́ , bóyá yóò un láradá ọjọ́ ìsinmi; wọn ̀láti fi ̀sùn kàn án. 8 Ṣùgbọ́n ó mọ èrò inú wọn, ó fún ọkùnrin náà ọwọ́ rẹ̀ rọ , "Dìde, o dúró láàrín." Ó dìde dúró.

9 Nígbà náà ni Jesu fún wọn , "Èmi bi yín léèrè, Ó ha tọ́ láti máa ṣe rere ni ọjọ́ ìsinmi, tàbí láti máa ṣe búburú? Láti gba ọkàn , tàbí láti pa á run?"

10 Nígbà ó wo gbogbo wọn yíká, ó fún ọkùnrin náà , "Na ọwọ́ rẹ." Ó ṣe bẹ́̀: ọwọ́ rẹ̀ padà bọ̀ sípò gẹ́gẹ́ èkejì.

Veja também