Publicidade

Lucas 9

Jesu rán ọmọ-ẹ̀yìn méjìlá lọ wàásù

1 Ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá jọ, ó fún wọn agbára àti àṣẹ lórí àwọn ̀èṣù gbogbo, àti láti wo ààrùn sàn. 2 Ó rán wọn lọ wàásù ìjọba Ọlọ́run, àti láti àwọn ọlọkùnrùn láradá. 3 Ó fún wọn , "ṣe nǹkan lọ́wọ́ fún àjò yín, ̀, tàbí àpò tàbí àkàrà, tàbí owó, bẹ́̀ ni ̀yin ṣe ̀méjì. 4 ilékílé ̀yin wọ̀, níbẹ̀ ni ̀yin gbé, láti ibẹ̀ ni ̀yin ti jáde. 5 Iye àwọn si gbà yín, nígbà ̀yin jáde kúrò ìlú náà, gbọn eruku ẹsẹ̀ yín fún ̀wọn." 6 Wọ́n lọ, wọ́n ń la ìletò kọjá wọ́n ń wàásù ìyìnrere, wọ́n ń ènìyàn láradá níbi gbogbo.

7 Herodu tetrarki gbọ́ nǹkan gbogbo èyí a ṣe láti ̀dọ̀ rẹ̀ : ó dààmú, nítorí àwọn ẹlòmíràn ń , Johanu ni ó jíǹde kúrò nínú òkú, 8 Àwọn ẹlòmíràn Elijah ni ó farahàn; àwọn ẹlòmíràn , ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde. 9 Herodu , "Johanu ni mo ti bẹ́ lórí, ṣùgbọ́n ta ni èyí èmi ń gbọ́ irú nǹkan wọ̀nyí ?" Ó ń fẹ́ láti i.

Jesu bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn

10 Nígbà àwọn aposteli padà , wọ́n ròyìn ohun gbogbo fún un wọ́n ti ṣe. Ó wọn, lọ apá kan níbi a ń Betisaida. 11 Nígbà ̀pọ̀ ènìyàn mọ̀, wọ́n tẹ̀e: ó gbà wọ́n, ó sọ̀rọ̀ ìjọba Ọlọ́run fún wọn; àwọn ó fẹ́ ìmúláradá, ni ó láradá.

12 Nígbà ọjọ́ bẹ̀rẹ̀ rọlẹ̀, àwọn méjìlá , wọ́n fún un , "ìjọ ènìyàn , wọn lọ ìletò àti ìlú yíká, wọn , àti wọn oúnjẹ: nítorí ijù ni àwa níhìn-ín."

13 Ṣùgbọ́n ó fún wọn , "fi oúnjẹ fún wọn jẹ!"

Wọ́n fún un , "Àwa ju ìṣù àkàrà márùn-ún lọ, pẹ̀ẹja méjì: ṣe àwa lọ ra oúnjẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí." 14 Nítorí àwọn ọkùnrin náà ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn.

Ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "wọ́n wọn jókòó lẹ́gbẹ̀̀gbẹ́, àràádọ́ta." 15 Wọ́n ṣe bẹ́̀, wọ́n gbogbo wọn jókòó. 16 Nígbà náà ni ó ìṣù àkàrà márùn-ún, àti ẹja méjì náà, nígbà ó gbé ojú sókè ̀run, ó súre i, ó ú, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọn gbé e kalẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn. 17 Wọ́n jẹ, gbogbo wọn : wọ́n ṣa agbọ̀n méjìlá jọ nínú àjẹkù ó .

Peteru pe Jesu Ọmọ Ọlọ́run

18 Ó ṣe, nígbà ó ku òun nìkan ó gbàdúrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ́dọ̀ rẹ̀: ó bi wọ́n , "Ta ni àwọn ènìyàn ń fi ?"

19 Wọ́n dáhùn , "Johanu Onítẹ̀bọmi; ṣùgbọ́n ẹlòmíràn Elijah ni, àti àwọn ẹlòmíràn , ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde."

20 Ó bi wọ́n , "Ṣùgbọ́n ta ni ̀yin ń fi èmi ?"

Peteru dáhùn, pe, "Kristi ti Ọlọ́run."

21 Ó kìlọ̀ fún wọn, , wọn ṣe sọ èyí fún ẹnìkan. 22 Ó , "Ọmọ ènìyàn yóò jìyà ohun púpọ̀, a ó kọ̀ ́ láti ̀dọ̀ àwọn alàgbà, olórí àlùfáà àti láti ̀dọ̀ àwọn akọ̀, a ó pa á, ọjọ́ kẹta a ó i dìde."

23 Ó fún gbogbo wọn , "ẹnìkan ń fẹ́ láti máa tọ̀ lẹ́yìn, ó sẹ́ ara rẹ̀, ó gbé àgbélébùú rẹ̀ ọjọ́ gbogbo, ó máa tọ̀ lẹ́yìn. 24 Nítorí ẹnikẹ́ni ó fẹ́ gba ọkàn rẹ̀ , yóò sọ ́ : ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó sọ ọkàn rẹ̀ nítorí mi, òun náà ni yóò gbà á . 25 Nítorí èrè kín ni fún ènìyàn, ó jèrè gbogbo ayé, ó sọ ara rẹ̀ tàbí ó fi ṣòfò. 26 Nítorí ẹnikẹ́ni ó tijú mi, àti ̀rọ̀ mi, òun ni Ọmọ Ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà ó inú ògo tirẹ̀, àti ti baba rẹ̀, àti ti àwọn angẹli mímọ́.

27 "Ṣùgbọ́n èmi fún yín nítòótọ́, ẹlòmíràn dúró níhìn-ín yìí, yóò ikú, títí wọn ó fi ìjọba Ọlọ́run."

Ìràpadà

28 Ó ṣe ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́jọ lẹ́yìn ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó Peteru àti Johanu àti Jakọbu, ó gun orí òkè lọ láti lọ gbàdúrà. 29 ó ti ń gbàdúrà, àwọ̀ ojú rẹ̀ yípadà, aṣọ rẹ̀ funfun gbòò, 30 kíyèsi i, àwọn ọkùnrin méjì, Mose àti Elijah, wọ́n ń a sọ̀rọ̀, 31 wọ́n fi ara hàn nínú ògo, wọ́n ń sọ̀rọ̀ ikú rẹ̀, òun yóò ṣe parí Jerusalẹmu. 32 Ṣùgbọ́n ojú Peteru àti ti àwọn ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ wúwo fún oorun. Nígbà wọ́n tají, wọ́n ògo rẹ̀, àti ti àwọn ọkùnrin méjèèjì ó a dúró. 33 Ó ṣe, nígbà wọ́n lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, Peteru fún Jesu , "Olùkọ́, ó dára fún wa a máa gbé ìhín yìí, jẹ́ àwa pa àgọ́ mẹ́ta, ̀kan fún ìwọ, àti ̀kan fún Mose, àti ̀kan fún Elijah." (mọ èyí òun ń .)

34 ó ti ń sọ báyìí, ìkùùkuu kan , ó síji wọ́n: ̀wọ́n nígbà wọ́n ń wọ inú ìkùùkuu lọ. 35 Ohùn kan ti inú ìkùùkuu , "Èyí yìí ni àyànfẹ́ ọmọ mi: máa gbọ́ tirẹ̀." 36 Nígbà ohùn náà dákẹ́, Jesu nìkan ṣoṣo ni a . Wọ́n pa á mọ́, wọn sọ ohunkóhun wọ́n fún ẹnikẹ́ni ọjọ́ wọ̀nyí.

Ìwòsàn ọmọkùnrin kan o ̀èṣù

37 Ó ṣe, ọjọ́ kejì, nígbà wọ́n sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, ̀pọ̀ àwọn ènìyàn pàdé rẹ̀. 38 kíyèsi i, ọkùnrin kan nínú ìjọ ènìyàn kígbe sókè , "Olùkọ́ mo bẹ̀ ́, wo ọmọ mi: nítorí ọmọ mi kan ṣoṣo náà ni. 39 kíyèsi i, ̀èṣù a máa un, a máa kígbe lójijì; a máa án tàntàn títí yóò fi yọ ìfófó lẹ́nu, a máa pa á lára, í tilẹ̀ ń fẹ́ fi í sílẹ̀ lọ. 40 Mo bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ láti e jáde: wọn ṣe é."

41 Jesu dáhùn , "Ìran aláìgbàgbọ́ àti àrékérekè, èmi ó ti yín gbé pẹ́ ? Èmi yóò ti ṣe sùúrù fún yín pẹ́ ? Fa ọmọ rẹ níhìn-ín yìí."

42 ó ti ń bọ̀, ̀èṣù náà gbé e ṣánlẹ̀, ó án tàntàn. Jesu ̀àìmọ́ náà , ó ọmọ náà láradá, ó á baba rẹ̀ lọ́wọ́. 43 Ẹnu ya gbogbo wọn iṣẹ́ títóbi Ọlọ́run, ṣùgbọ́n nígbà ń ṣe gbogbo wọn ohun gbogbo Jesu ṣe, ó fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , 44 "jẹ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí wọ̀ yín létí, nítorí a ó fi Ọmọ Ènìyàn àwọn ènìyàn lọ́wọ́." 45 Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ náà wọn, ó ṣú wọn lójú, bẹ́̀ ni wọn mọ̀ ́n: ̀ń wọ́n láti béèrè ìdí ̀rọ̀ náà.

Ta ni o ga jùlọ

46 Iyàn kan dìde láàrín wọn, ti ẹni yóò ṣe olórí nínú wọn. 47 Nígbà Jesu mọ èrò ọkàn wọn, ó ọmọdé kan, ó gbé e jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀. 48 Ó fún wọn , "Ẹnikẹ́ni ó gba ọmọdé yìí nítorí orúkọ mi, ó gbà : àti ẹnikẹ́ni ó gbà , ó gba ẹni ó rán mi: nítorí ẹni ó kéré nínú gbogbo yín, òun náà ni yóò pọ̀."

49 Johanu dáhùn ó fún un , "Olùkọ́, àwa ẹnìkan ó ń fi orúkọ rẹ àwọn ̀èṣù jáde; àwa a lẹ́kun, nítorí wa tọ̀ ́ lẹ́yìn."

50 Jesu fún un, , "ṣe a lẹ́kun mọ́: nítorí ẹni lòdì i yín, ó fún yín."

Ìtakò àwọn ará Samaria

51 Nígbà ọjọ́ àti gbà á sókè ń súnmọ́, ó pinnu láti lọ Jerusalẹmu. 52 Ó rán àwọn ìránṣẹ́ lọ iwájú rẹ̀. Nígbà wọ́n lọ wọ́n wọ ìletò kan í ṣe ti ará Samaria láti pèsè sílẹ̀ é. 53 Wọn gbà á, nítorí ó ń lọ Jerusalẹmu. 54 Nígbà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Jakọbu àti Johanu i, wọ́n , "Olúwa wa, jẹ́ a pe iná láti ̀run , a pa wọ́n run, Elijah ti ṣe?" 55 Ṣùgbọ́n Jesu yípadà, ó wọn . 56 Lẹ́yìn náà Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lọ ìletò mìíràn.

Ìpinnu láti tọ Jesu lẹ́yìn

57 wọ́n ti ń lọ lọ́, ọkùnrin kan fún un , "Olúwa, Èmi ń fẹ́ láti máa tọ̀ ́ lẹ́yìn ibikíbi ìwọ ń lọ."

58 Jesu fún un , "Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ihò, àwọn ẹyẹ ojú ̀run ìtẹ́; ṣùgbọ́n Ọmọ Ènìyàn ibi yóò fi orí rẹ̀ ."

59 Ó fún ẹlòmíràn , "Máa tọ̀ lẹ́yìn."

Ṣùgbọ́n èyí fún un , "Olúwa, jẹ́ èmi lọ sìnkú baba mi ."

60 Jesu fún un , "Jẹ́ àwọn òkú máa sìnkú ara wọn, ṣùgbọ́n ìwọ lọ o máa wàásù ìjọba Ọlọ́run."

61 Ẹlòmíràn fún un , "Olúwa, èmi yóò tọ̀ ́ lẹ́yìn ṣùgbọ́n jẹ́ n kọ́kọ́ lọ dágbére fún àwọn ará ilé mi."

62 Jesu fún un , "ẹni, ó fi ọwọ́ rẹ̀ ohun èlò ìtulẹ̀, ó wo ̀yìn, ó yẹ fún ìjọba Ọlọ́run."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-