Publicidade

Marcos 1

Johanu onítẹ̀bọmi tún ̀ṣe sílẹ̀

1 Ìbẹ̀rẹ̀ ìyìnrere nípa Jesu Kristi, Ọmọ Ọlọ́run.

2 Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú ìwé wòlíì Isaiah ,

"Èmi yóò ran oníṣẹ́ mi síwájú rẹ,

Ẹni yóò tún ̀rẹ ṣe."

3 "Ohùn ẹni ń kígbe ijù,

tún ̀Olúwa ṣe,

ṣe ojú ̀rẹ̀ ó tọ́.’ "

4 Johanu , ẹni ó ń tẹnibọmi aginjù, ó ń wàásù ìtẹ̀bọmi ìrònúpìwàdà fún ìdáríjì ̀ṣẹ̀. 5 Gbogbo àwọn ń gbé agbègbè Judea, àti gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu jáde tọ̀ ́ lọ, a ti ọwọ́ rẹ̀ tẹ gbogbo wọn bọ omi ni odò Jordani, wọ́n ń jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ wọn. 6 Johanu wọ aṣọ irun ìbákasẹ. Ó di àmùrè awọ mọ́ ̀gbẹ́ rẹ̀. Eṣú àti oyin ìgàn ni oúnjẹ rẹ̀. 7 Ó bẹ̀rẹ̀ í wàásù , "Ẹnìkan ó tóbi lọ ń bọ̀ lẹ́yìn mi, okùn bàtà ẹsẹ̀ ẹni èmi ẹni ń . 8 Èmi ń fi omi ṣe ìtẹ̀bọmi yín, ṣùgbọ́n Òun yóò fi ̀Mímọ́ ṣe ìtẹ̀bọmi yín."

Ìtẹ̀bọmi àti ìdánwò Jesu

9 Ó ṣe ọjọ́ kan Jesu ti Nasareti ti Galili jáde , a ti ọwọ́ Johanu ṣe ìtẹ̀bọmi fún odò Jordani. 10 Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ Jesu ń ti inú omi jáde , ó ̀run ó ṣí sílẹ̀, ̀Mímọ́ àdàbà sọ̀kalẹ̀ e lórí. 11 Ohùn kan ti ̀run , "Ìwọ ni àyànfẹ́ Ọmọ mi, ẹni inú mi dùn gidigidi."

12 Lẹ́sẹ̀kan náà, ̀Mímọ́ darí Jesu ijù, 13 Ó ogójì ọjọ́ aginjù. A ti ọwọ́ Satani dán an , ó pẹ̀àwọn ẹranko ìgbẹ́. Àwọn angẹli ń ṣe ìránṣẹ́ fún un.

Pípe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àkọ́kọ́

14 Lẹ́yìn ìgbà ọba Herodu ti fi Johanu sínú ̀wọ̀n tan, Jesu lọ Galili, ó ń wàásù ìyìnrere ti ìjọba Ọlọ́run. 15 Ó kéde , "Àkókò náà wàyí, ìjọba Ọlọ́run dẹ̀dẹ̀. yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ yín, gba ìyìnrere yìí gbọ́."

16 ọjọ́ kan, Jesu ti ń rìn létí Òkun Galili, Ó Simoni àti Anderu arákùnrin rẹ̀, wọ́n ń fi àwọ̀n wọn pẹja torí apẹja ni wọ́n. 17 Jesu wọn , "máa tọ̀ lẹ́yìn. Èmi yóò sọ yín di apẹja ènìyàn." 18 kánkán wọ́n fi àwọ̀n wọn sílẹ̀, wọ́n tọ̀ ́ lẹ́yìn.

19 Ó ti rìn síwájú díẹ̀, etí Òkun, Ó Jakọbu ọmọ Sebede àti Johanu arákùnrin rẹ̀ nínú ọkọ̀, wọ́n ń tún àwọ̀n wọn ṣe. 20 Ó àwọn náà lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, wọ́n fi Sebede baba wọn sílẹ̀ nínú ọkọ̀ pẹ̀àwọn alágbàṣe, wọ́n tọ̀ ́ lẹ́yìn.

Jesu ̀àìmọ́ jáde

21 Lẹ́yìn náà, Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ ìlú Kapernaumu, nígbà ó di òwúrọ̀ ọjọ́ ìsinmi, ó lọ sínú Sinagọgu, ó ń kọ́ni. 22 Ẹnu ya ìjọ ènìyàn nítorí ìkọ́ni rẹ̀, nítorí ó ń kọ́ni ẹni ó àṣẹ, í ṣe àwọn olùkọ́ òfin ṣe ń kọ́ àwọn ènìyàn. 23 àsìkò náà gan an ni ọkùnrin kan ó nínú Sinagọgu wọn, ó ̀àìmọ́, bẹ̀rẹ̀ í kígbe , 24 "ni ìwọ ń lọ́dọ̀ wa, Jesu ti Nasareti? Ṣé ìwọ láti pa run ni? Èmí mọ ẹni ìwọ í ṣe; Ìwọ ẹni Mímọ́ Ọlọ́run!"

25 Jesu si a , ó , "Pa ẹnu rẹ mọ́, ó jáde kúrò lára rẹ̀." 26 ̀àìmọ́ náà gbé e ṣánlẹ̀ lógèdèǹgbé, ó ohùn rara, ó jáde kúrò lára ọkùnrin náà.

27 Ẹnu ya àwọn ènìyàn, bẹ́̀ wọ́n fi ń sọ láàrín ara wọn ohun ó ti ṣẹlẹ̀. Wọ́n béèrè pẹ̀ìgbóná ara, , "ni èyí? Irú ̀kọ́ tuntun wo ni èyí? Ó ń fi agbára pàṣẹ fún àwọn ̀àìmọ́ pàápàá wọ́n gbọ́ tirẹ̀." 28 Ìròyìn nípa rẹ̀ tàn gbogbo agbègbè Galili.

Jesu ̀pọ̀ ènìyàn láradá

29 Nígbà wọn jáde kúrò nínú Sinagọgu, wọ́n lọ pẹ̀Jakọbu àti Johanu ilé Simoni àti Anderu. 30 Ìyá ìyàwó Simoni ó dùbúlẹ̀ àìsàn ibà, wọ́n sọ fún Jesu nípa rẹ̀. 31 Ó tọ̀ ́ lọ, ó á lọ́wọ́, ó gbé e dìde; lójúkan náà ibà náà fi sílẹ̀, ó ń ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.

32 Nígbà ó di àṣálẹ́, oòrùn wọ̀, wọ́n gbé gbogbo àwọn aláìsàn àti àwọn ni ̀àìmọ́ tọ̀ ́ . 33 Gbogbo ìlú si péjọ ni ẹnu-ọ̀. 34 Jesu wo ̀pọ̀ wọ́n onírúurú ààrùn sàn. Bákan náà ni ó ̀pọ̀ ̀àìmọ́ jáde. Ṣùgbọ́n jẹ́ àwọn ̀àìmọ́ náà ó sọ̀rọ̀, nítorí wọ́n mọ ẹni òun í ṣe.

Jesu ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ láti gbàdúrà

35 kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ilẹ̀ mọ́, Jesu nìkan jáde lọ aginjù kan, láti lọ gbàdúrà. 36 Simoni àti àwọn ènìyàn rẹ̀ yòókù lọ láti a. 37 Nígbà wọ́n I, wọ́n sọ fún , "Gbogbo ènìyàn ń !"

38 Jesu dáhùn , "jẹ́ a lọ àwọn ìlú mìíràn, ń wàásù níbẹ̀ pẹ̀. Nítorí èyí ni èmi à ṣe ." 39 Nítorí náà, ó ń kiri gbogbo agbègbè Galili, ó ń wàásù nínú Sinagọgu. Ó ń àwọn ̀àìmọ́ jáde.

Ọkùnrin o ààrùn ̀tẹ̀

40 Ọkùnrin adẹ́tẹ̀ kan tọ̀ ́ , ó kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀. Ó bẹ̀bẹ̀ fún ìmúláradá. Ó , "ìwọ fẹ́, ìwọ mi láradá."

41 Jesu kún fún àánú, ó na ọwọ́ rẹ̀, ó fi ọwọ́ rẹ̀ a, ó , "Èmí fẹ́. Di mímọ́." 42 Lójúkan náà ̀tẹ̀ náà fi sílẹ̀ lọ, ọkùnrin náà ìwòsàn.

43 Jesu kìlọ̀ fún un gidigidi 44 Ó , "Lọ fi ara rẹ̀ hàn àlùfáà Júù fún àyẹ̀. Ṣùgbọ́n ṣe dúró sọ ohunkóhun fún ẹnikẹ́ni ̀. ̀bùn lọ́wọ́, èyí Mose pàṣẹ fún adẹ́tẹ̀ a láradá. Èyí í ṣe ̀, ó ti ìwòsàn." 45 Ṣùgbọ́n ó jáde lọ, ó bẹ̀rẹ̀ í pòkìkí, ó ń tan ìròyìn kálẹ̀. Nítorí èyí, Jesu le wọ ìlú gbangba mọ́, ṣùgbọ́n ó lẹ́yìn odi ìlú aginjù. Síbẹ̀, àwọn ènìyàn tọ̀ ́ láti ibi gbogbo.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-